ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • sn orin 58
  • Àdúrà Ìyàsímímọ́ Mi

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àdúrà Ìyàsímímọ́ Mi
  • Kọrin sí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Àdúrà Ìyàsímímọ́ Mi
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Orin Tuntun
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Orin Tuntun
    Kọrin sí Jèhófà
  • Máa Fi Orin Yin Jèhófà
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
Àwọn Míì
Kọrin sí Jèhófà
sn orin 58

Orin 58

Àdúrà Ìyàsímímọ́ Mi

Bíi Ti Orí Ìwé

(Mátíù 22:37)

1. Gba ọkàn mi, jẹ́ kó fẹ́

Òótọ́ òun ọgbọ́n tọ̀run.

Gbàrònú mi, Jèhófà,

Kí nlè sìn lẹ́kùn-ún rẹ́rẹ́.

2. Gba ọwọ́ àtẹsẹ̀ mi;

Kí wọ́n máa ṣohun tóo fẹ́.

Gba ohùn mi jẹ́ kó máa

Kọrin ìyìn sọ́ba mi.

3. Gba ayé mi Ọlọ́run,

Mú kó bá ìfẹ́ rẹ mu.

Gba èmi gan-an kíwà mi

Lè máa wù ọ́ Olúwa.

(Tún wo Sm. 40:8; Jòh. 8:29; 2 Kọ́r. 10:5.)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́