ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • sn orin 65
  • “Èyí Ni Ọ̀nà”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • “Èyí Ni Ọ̀nà”
  • Kọrin sí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • “Èyí Ni Ọ̀nà”
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Ẹ̀bùn Ni Àwọn Olùṣọ́ Àgùntàn
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Báwo Ló Ṣe Máa Ń Rí Lára Rẹ?
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Àwọn Olùṣọ́ Àgùntàn Jẹ́ Ẹ̀bùn
    Kọrin sí Jèhófà
Àwọn Míì
Kọrin sí Jèhófà
sn orin 65

Orin 65

“Èyí Ni Ọ̀nà”

Bíi Ti Orí Ìwé

(Aísáyà 30:20, 21)

1. Ọ̀nà ayọ̀ kan wà,

Ọ̀nà tóo ti kọ́ ni.

Ọ̀nà tóo ti mọ̀ ni,

Ọ̀nà tó ti pẹ́ ni,

Ọ̀nà tí Jésù kọ́ọ

Nígbà tóo gbóhùn rẹ̀.

Èyí lọ̀nà ayọ̀,

Táa rí ń’nú Bíbélì.

(ÈGBÈ)

Èyí ni Ọ̀nà náà, Ọ̀nà ìyè.

Má yà bàrá; Má ṣe wọ̀tún wòsì!

Ọlọ́run ńwí pé: ‘Èyí lọ̀nà.

Má ṣe wẹ̀yìn, torí Èyí lọ̀nà.’

2. Ọ̀nà ìfẹ́ kan wà,

Má ṣe dààmú kiri.

Jáà ti fi wá mọ̀nà;

Ó fara rẹ̀ hàn wá.

Ìfẹ́ rẹ̀ pọ̀ púpọ̀;

Ìfẹ́ tòótọ́ sì ni.

Èyí lọ̀nà ìfẹ́;

Ó sì ńhàn láyé wa.

(ÈGBÈ)

Èyí ni Ọ̀nà náà, Ọ̀nà ìyè.

Má yà bàrá; Má ṣe wọ̀tún wòsì!

Ọlọ́run ńwí pé: ‘Èyí lọ̀nà.

Má ṣe wẹ̀yìn, torí Èyí lọ̀nà.’

3. Ọ̀nà ìyè kan wà,

Má ṣe bojú wẹ̀yìn.

Ọlọ́run ti sọ pé:

Kò sọ́nà rere míì,

Kò sọ́nà ayọ̀ míì,

Kò sọ́nà ìfẹ́ míì.

Èyí lọ̀nà ìyè,

Ọpẹ́ yẹ Ọlọ́run.

(ÈGBÈ)

Èyí ni Ọ̀nà náà, Ọ̀nà ìyè.

Má yà bàrá; Má ṣe wọ̀tún wòsì!

Ọlọ́run ńwí pé: ‘Èyí lọ̀nà.

Má ṣe wẹ̀yìn, torí Èyí lọ̀nà.’

(Tún wo Sm. 32:8; 139:24; Òwe 6:23.)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́