ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • sn orin 48
  • Bíbá Jèhófà Rìn Lójoojúmọ́

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Bíbá Jèhófà Rìn Lójoojúmọ́
  • Kọrin sí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Máa Bá Jèhófà Rìn Lójoojúmọ́
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Ṣé Wàá Bá Ọlọ́run Rìn?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2005
  • Bá Ọlọ́run Rìn!
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • A Mọyì Inú Rere Àìlẹ́tọ̀ọ́sí Tí Ọlọ́run Ń Fi Hàn sí Wa
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2016
Àwọn Míì
Kọrin sí Jèhófà
sn orin 48

Orin 48

Bíbá Jèhófà Rìn Lójoojúmọ́

Bíi Ti Orí Ìwé

(Míkà 6:8)

1. Baba wa ló ńfà wá lọ́wọ́,

A sì ńfi ìrẹ̀lẹ̀ bá a rìn.

Inú rere àìlẹ́tọ̀ọ́sí

Tó fáwọn tó ńwá ọ̀nà rẹ̀ pọ̀!

Ọlọ́run ti ṣètò fún wa

Ká bàa lè dìí lọ́wọ́ mú.

A ti yara wa sí mímọ́;

A dúró sọ́dọ̀ Jèhófà.

2. Bí òpin ti ńsún mọ́lé yìí,

Tí ìdájọ́ ayé ńlọ lọ́wọ́,

Àtakò tó ńdojú kọ wá

Lè fẹ́ mú kí ẹ̀rù máa bà wá.

Jèhófà ló ńdáàbò bò wá;

Ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ la fẹ́ máa wà

Ká bàa lè máa sìnín títí láé.

Ká nífẹ̀ẹ́ rẹ̀, ká dúró gbọn-in.

3. Ọlọ́run ńpèsè ìrànwọ́

Nípa ẹ̀mí àti Ọ̀rọ̀ rẹ̀,

Nípa ìjọ Kristẹni rẹ̀,

Nípa àdúrà wa tó ń gbọ́.

Báa sì ṣe ńbá Jèhófà rìn,

Yóò jẹ́ ká ṣohun tó tọ́,

Yóò jẹ́ ká ní inú rere,

Aó fi ìrẹ̀lẹ̀ bá a rìn.

(Tún wo Jẹ́n. 5:24; 6:9; 1 Ọba 2:3, 4.)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́