ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • sn orin 10
  • “Èmi Nìyí! Rán Mi”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • “Èmi Nìyí! Rán Mi”
  • Kọrin sí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Èmi Nìyí! Rán Mi!”
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Ìyè Àìnípẹ̀kun Nígbẹ̀yìn-gbẹ́yín!
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • À Ń Múra Láti Lọ Wàásù
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • À Ń Múra Láti Lọ Wàásù
    Kọrin sí Jèhófà—Àwọn Orin Tuntun
Àwọn Míì
Kọrin sí Jèhófà
sn orin 10

Orin 10

“Èmi Nìyí! Rán Mi”

Bíi Ti Orí Ìwé

(Aísáyà 6:8)

1. Ayé ńkẹ́gàn òun ìtìjú,

Bá oókọ ògo Ọlọ́run.

Ẹlòmíì ńpèé ní òǹrorò.

Òpònú ní: “Kò s’Ọ́lọ́run!”

Ta ni yóò lọ kéde òótọ́?

Táá máa yin oókọ Ọlọ́run?

‘Olúwa, Èmi rèé! Rán mi.

Nó fòótọ́ kọrin ìyìn rẹ.

(Ègbè)

Ọlá kan kò jùyí, Olúwa.

Èmi rèé! Rán mi, rán mi.’

2. Ẹ̀dá ńsọ p’Ọ́lọ́run lọ́ra;

Wọn kò níbẹ̀rù Ọlọ́run.

Wọ́n ńbọ̀rìṣà, bọgi, bọ̀pẹ̀;

Késárì di Ọlọ́run wọn.

Ta ni yóò kìlọ̀ fẹ́ni’bi?

Táá kìlọ̀ Amágẹ́dọ́nì?

‘Olúwa, Èmi rèé! Rán mi.

Nó kìlọ̀ fún wọn láìbẹ̀rù.

(Ègbè)

Ọlá kan kò jùyí, Olúwa.

Èmi rèé! Rán mi, rán mi.’

3. Lónìí onírẹ̀lẹ̀ ńkẹ́dùn

Torí ibi túbọ̀ ńpọ̀ síi.

Wọ́n ńfi ọkàn mímọ́ wádìí

Òótọ́ táá fọkàn wọn balẹ̀.

Ta ni yóò mútùnú tọ̀ wọ́n?

Táá tọ́ wọn sọ́nà òdodo?

‘Olúwa, Èmi rèé! Rán mi.

Nó fi sùúrù kọ́ ońrẹ̀lẹ̀.

(ÈGBÈ)

Ọlá kan kò jùyí, Olúwa.

Èmi rèé! Rán mi, rán mi.’

(Tún wo Sm. 10:4; Ìsík. 9:4.)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́