ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • sn orin 96
  • Ẹ Wá Àwọn Ẹni Yíyẹ Kàn

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ẹ Wá Àwọn Ẹni Yíyẹ Kàn
  • Kọrin sí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ẹ Wá Àwọn Ẹni Yíyẹ Kàn
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Jèhófà, Ọlọ́run Atóbilọ́lá
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Ìrìn Àjò Iwaasu Miiran ní Galili
    Ọkunrin Titobilọla Julọ Ti O Tii Gbé Ayé Rí
  • Jẹ́ Onínú Tútù Bíi Kristi
    Kọrin sí Jèhófà
Àwọn Míì
Kọrin sí Jèhófà
sn orin 96

Orin 96

Ẹ Wá Àwọn Ẹni Yíyẹ Kàn

Bíi Ti Orí Ìwé

(Mátíù 10:11-15)

1. Olúwa wa kọ́ wa níṣẹ́ ìwàásù,

Ohun tó sọ fún wa ni pé:

‘Níbikíbi tẹ́ẹ bá lọ, ẹ wá àwọn

Táìní wọn tẹ̀mí ńjẹ lọ́kàn rí.

Bẹ́ẹ ṣe ńkí ońlé pé àlàáfíà fún wọn,

Àlàáfíà yóò bá ẹni yíyẹ.

Táwọn kan bá láwọn ò fẹ́ gbọ́, ẹ gbọn

Ekuru ẹsẹ̀ yín sílẹ̀ ńbẹ̀.’

2. Àwọn tó bá gbà yín ti gba òun pẹ̀lú.

Ọlọ́run yóò là wọ́n lóye.

Ìfẹ́ tí wọ́n ní síyè àìnípẹ̀kun

Yóò mú kí wọ́n dara pọ̀ mọ́ yín.

Ẹ má sì ṣàníyàn ohun tẹ́ó sọ láé.

Jèhófà yóò gbẹnu yín sọ̀rọ̀.

Tí ìdáhùn yín bá níyọ̀ tó sì dáa,

Yóò wọ àwọn ońrẹ̀lẹ̀ lọ́kàn.

(Tún wo Ìṣe 13:48; 16:14; Kól. 4:6.)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́