ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • sjj orin 105
  • “Ọlọ́run Jẹ́ Ìfẹ́”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • “Ọlọ́run Jẹ́ Ìfẹ́”
  • “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • “Ọlọ́run Jẹ́ Ìfẹ́”
    Kọrin sí Jèhófà
  • Bá a Ṣe Lè Nífẹ̀ẹ́ Ọmọnìkejì Wa
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2006
  • ‘Ẹ Máa Rìn Nínú Ìfẹ́’
    Sún Mọ́ Jèhófà
  • Nífẹ̀ẹ́ Ọlọ́run Tó Nífẹ̀ẹ́ Rẹ
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2006
Àwọn Míì
“Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
sjj orin 105

ORIN 105

“Ọlọ́run Jẹ́ Ìfẹ́”

Bíi Ti Orí Ìwé

(1 Jòhánù 4:7, 8)

  1. 1. Bàbá wa ọ̀run jẹ́ ìfẹ́,

    Ó ní káwa náà nífẹ̀ẹ́.

    Tá a bá nífẹ̀ẹ́ Ọlọ́run wa,

    Tá a nífẹ̀ẹ́ àwọn èèyàn,

    Ìgbé ayé wa á ládùn,

    Ó sì máa jẹ́ ká níyè.

    Jésù Kristi náà fìfẹ́ hàn;

    Ká tẹ̀ lé àpẹẹrẹ rẹ̀.

  2. 2. Ìfẹ́ tòótọ́ máa ń ta wá jí;

    Ó máa ń mú ká fìfẹ́ hàn.

    Ìfẹ́ tá a ní sí Ọlọ́run

    Máa s’agbára wa dọ̀tun.

    Ìfẹ́ máa ń ṣoore, kìí jowú;

    Ìfẹ́ máa ń ní ‘faradà.

    Ẹ jẹ́ ká nífẹ̀ẹ́ ara wa;

    Ká gbádùn ìfẹ́ tòótọ́.

  3. 3. Má di ẹnikẹ́ni sínú;

    Má fàyè gba ìbínú.

    Jèhófà ni kó o yíjú sí,

    Àwọn òfin rẹ̀ dára.

    Ẹ jẹ́ ká nífẹ̀ẹ́ Ọlọ́run,

    Yóò mú kífẹ̀ẹ́ wa jinlẹ̀.

    Ká fara wé Ọlọ́run wa;

    Ká nífẹ̀ẹ́ gbogbo èèyàn.

(Tún wo Máàkù 12:​30, 31; 1 Kọ́r. 12:31–13:8; 1 Jòh. 3:23.)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́