ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • nwt ojú ìwé 1235
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Jóẹ́lì

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Jóẹ́lì
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ta Ni Yóò “Yè Bọ́”?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1998
  • A Mú Ìdájọ́ Ṣẹ Ní Pẹ̀tẹ́lẹ̀ Rírẹlẹ̀ Ti Ìpinnu
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1998
  • Dúró sí “Àfonífojì Àwọn Òkè Ńlá”
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Ẹ Pa Ọjọ Jehofa Mọ́ Sọ́kàn Pẹkipẹki
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1992
Àwọn Míì
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Jóẹ́lì

JÓẸ́LÌ

OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ

  • 1

    • Àwọn kòkòrò ṣọṣẹ́ gan-an (1-14)

    • “Ọjọ́ Jèhófà sún mọ́lé” (15-20)

      • Wòlíì náà ké pe Jèhófà (19, 20)

  • 2

    • Ọjọ́ Jèhófà àti àwọn ọmọ ogun rẹ̀ (1-11)

    • Ìkésíni láti pa dà sọ́dọ̀ Jèhófà (12-17)

      • “Ọkàn yín ni kí ẹ fà ya” (13)

    • Ohun tí Jèhófà sọ fún àwọn èèyàn rẹ̀ (18-32)

      • “Èmi yóò tú ẹ̀mí mi” (28)

      • Àwọn ohun ìyanu lójú ọ̀run àti ní ayé (30)

      • Àwọn tó ń ké pe orúkọ Jèhófà yóò rí ìgbàlà (32)

  • 3

    • Jèhófà dá gbogbo orílẹ̀-èdè lẹ́jọ́ (1-17)

      • Àfonífojì Jèhóṣáfátì (2, 12)

      • Àfonífojì ìpinnu (14)

      • Jèhófà jẹ́ odi ààbò Ísírẹ́lì (16)

    • Jèhófà ń bù kún àwọn èèyàn rẹ̀ (18-21)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́