19 Èmi yóò fún Áárónì àti àwọn ọmọ rẹ̀ ní àwọn ọmọ Léfì bí àwọn tí a fi fúnni láàárín àwọn ọmọ Ísírẹ́lì, kí wọ́n lè máa ṣiṣẹ́ nínú àgọ́ ìpàdé+ fún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì, kí wọ́n sì máa ṣe ètùtù fún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì,+ kí ìyọnu má bàa dé bá àwọn ọmọ Ísírẹ́lì torí wọ́n sún mọ́ ibi mímọ́.”