ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 101
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Sáàmù

      • Alákòóso tó ń hu ìwà títọ́

        • ‘Mi ò ní gba ìgbéraga láyè’ (5)

        • “Màá bojú wo àwọn olóòótọ́” (6)

Sáàmù 101:àkọlé

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

Sáàmù 101:1

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “kọrin sí.”

Sáàmù 101:2

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ìwà títọ́.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Ọb 9:4; Sm 78:70, 72

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    11/1/2005, ojú ìwé 24-25

    7/15/1998, ojú ìwé 27

Sáàmù 101:3

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ohun tí kò wúlò.”

  • *

    Tàbí “Ìwà wọn kò mọ́ mi lára.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 97:10

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    7/15/2011, ojú ìwé 13

Sáàmù 101:4

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “mọ.”

Sáàmù 101:5

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “mú un kúrò.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Owe 20:19

Sáàmù 101:6

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “nínú ìwà títọ́.”

Sáàmù 101:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “lọ́dọ̀.”

Sáàmù 101:8

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “mú gbogbo àwọn ẹni burúkú ayé kúrò.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Owe 20:8

Àwọn míì

Sm 101:21Ọb 9:4; Sm 78:70, 72
Sm 101:3Sm 97:10
Sm 101:5Owe 20:19
Sm 101:8Owe 20:8
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Sáàmù 101:1-8

Sáàmù

Ti Dáfídì. Orin.

101 Màá kọrin nípa ìfẹ́ tí kì í yẹ̀ àti ìdájọ́ òdodo.

Jèhófà, ìwọ ni màá kọ orin ìyìn sí.*

 2 Màá hu ìwà ọgbọ́n àti ìwà àìlábààwọ́n.*

Ìgbà wo lo máa wá bá mi?

Màá fi òtítọ́ ọkàn+ rìn nínú ilé mi.

 3 Mi ò ní gbé ohun tí kò ní láárí* sí iwájú mi.

Mo kórìíra iṣẹ́ àwọn tó ń yà kúrò nínú ohun tí ó tọ́;+

Mi ò ní bá wọn da nǹkan kan pọ̀.*

 4 Ọkàn ẹ̀tàn jìnnà sí mi;

Mi ò ní gba* ohun búburú kankan.

 5 Ẹnikẹ́ni tó bá ń ba ọmọnìkejì rẹ̀ jẹ́ ní ìkọ̀kọ̀,+

Màá pa á lẹ́nu mọ́.*

Ẹnikẹ́ni tó bá ní ojú ìgbéraga àti ọkàn gíga,

Mi ò ní gbà á láyè.

 6 Màá bojú wo àwọn olóòótọ́ ayé,

Kí wọ́n lè máa bá mi gbé.

Ẹni tó ń rìn láìní àbààwọ́n* yóò máa ṣe ìránṣẹ́ fún mi.

 7 Kò sí ẹlẹ́tàn kankan tó máa gbé inú ilé mi,

Kò sì sí òpùrọ́ kankan tó máa dúró níwájú* mi.

 8 Ní àràárọ̀, màá pa gbogbo àwọn ẹni burúkú ayé lẹ́nu mọ́,*

Láti mú gbogbo àwọn aṣebi kúrò ní ìlú Jèhófà.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́