ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • 2 Sámúẹ́lì 12
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 2 Sámúẹ́lì

      • Nátánì bá Dáfídì wí (1-15a)

      • Ọmọ Bátí-ṣébà kú (15b-23)

      • Bátí-ṣébà bí Sólómọ́nì (24, 25)

      • Dáfídì gba ìlú Rábà tó jẹ́ ti àwọn ọmọ Ámónì (26-31)

2 Sámúẹ́lì 12:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Ọb 1:8; 1Kr 17:1; 29:29
  • +Sm 51:àkọlé

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    5/1/2010, ojú ìwé 30

2 Sámúẹ́lì 12:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 5:13; 15:16

2 Sámúẹ́lì 12:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 11:3

2 Sámúẹ́lì 12:4

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 11:4

2 Sámúẹ́lì 12:5

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 6:13

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    5/1/2010, ojú ìwé 30

2 Sámúẹ́lì 12:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 22:1

2 Sámúẹ́lì 12:7

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 16:13; 2Sa 7:8
  • +1Sa 18:10, 11; 19:10; 23:14

2 Sámúẹ́lì 12:8

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 13:13, 14; 15:26, 28
  • +2Sa 3:7; 1Ọb 2:22
  • +2Sa 2:4; 5:5
  • +2Sa 7:19

2 Sámúẹ́lì 12:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 20:13
  • +Ẹk 20:14, 17
  • +2Sa 11:15, 27

2 Sámúẹ́lì 12:10

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 14:18; 2Sa 13:32; 18:33; Ga 6:7

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    5/1/2010, ojú ìwé 30

2 Sámúẹ́lì 12:11

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ọmọnìkejì rẹ.”

  • *

    Ní Héb., “ní ojú oòrùn yìí.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 12:15, 19; 13:10-15; 15:14
  • +Ẹk 21:24; Job 31:9-11; 34:11
  • +2Sa 16:21, 22

2 Sámúẹ́lì 12:12

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “iwájú oòrùn.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 11:4, 15

2 Sámúẹ́lì 12:13

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ti jẹ́ kí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ kọjá lọ.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 39:9; Sm 32:5; 38:3; 51:àkọlé; 51:4; Owe 28:13
  • +Ẹk 34:6; Sm 32:1
  • +Le 20:10; Sm 103:10

2 Sámúẹ́lì 12:16

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 12:22; Jon 3:8, 9

2 Sámúẹ́lì 12:20

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ààfin.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Rut 3:3; 2Sa 14:2
  • +2Sa 6:17

2 Sámúẹ́lì 12:22

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 12:16; Joẹ 1:14
  • +Ais 38:3, 5; Joẹ 2:13, 14; Emọ 5:15; Jon 3:8, 9

2 Sámúẹ́lì 12:23

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Onw 9:6
  • +Job 30:23; Onw 3:20; Iṣe 2:29, 34; 13:36
  • +Onw 9:5, 10

2 Sámúẹ́lì 12:24

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Látinú ọ̀rọ̀ Hébérù tó túmọ̀ sí “Àlàáfíà.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 11:3
  • +1Kr 3:5, 9; 22:9; 28:5; Mt 1:6
  • +2Sa 7:12; 1Kr 29:1

2 Sámúẹ́lì 12:25

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ó túmọ̀ sí “Àyànfẹ́ Jáà.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 7:4, 5; 12:1; 1Ọb 1:8

2 Sámúẹ́lì 12:26

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ìlú ìjọba.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 3:11; Joṣ 13:24, 25
  • +Di 23:3, 6
  • +2Sa 11:25; 1Kr 20:1

2 Sámúẹ́lì 12:27

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ó ṣeé ṣe kó máa tọ́ka sí ibi tí omi ìlú náà ti ń wá.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 11:1

2 Sámúẹ́lì 12:28

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “wọ́n á sì máa fi orúkọ mi pè é.”

2 Sámúẹ́lì 12:30

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tálẹ́ńtì kan jẹ́ kìlógíráàmù 34.2. Wo Àfikún B14.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 8:11, 12
  • +1Kr 20:2, 3

2 Sámúẹ́lì 12:31

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    2/15/2005, ojú ìwé 27

Àwọn míì

2 Sám. 12:11Ọb 1:8; 1Kr 17:1; 29:29
2 Sám. 12:1Sm 51:àkọlé
2 Sám. 12:22Sa 5:13; 15:16
2 Sám. 12:32Sa 11:3
2 Sám. 12:42Sa 11:4
2 Sám. 12:5Di 6:13
2 Sám. 12:6Ẹk 22:1
2 Sám. 12:71Sa 16:13; 2Sa 7:8
2 Sám. 12:71Sa 18:10, 11; 19:10; 23:14
2 Sám. 12:81Sa 13:13, 14; 15:26, 28
2 Sám. 12:82Sa 3:7; 1Ọb 2:22
2 Sám. 12:82Sa 2:4; 5:5
2 Sám. 12:82Sa 7:19
2 Sám. 12:9Ẹk 20:13
2 Sám. 12:9Ẹk 20:14, 17
2 Sám. 12:92Sa 11:15, 27
2 Sám. 12:10Nọ 14:18; 2Sa 13:32; 18:33; Ga 6:7
2 Sám. 12:112Sa 12:15, 19; 13:10-15; 15:14
2 Sám. 12:11Ẹk 21:24; Job 31:9-11; 34:11
2 Sám. 12:112Sa 16:21, 22
2 Sám. 12:122Sa 11:4, 15
2 Sám. 12:13Jẹ 39:9; Sm 32:5; 38:3; 51:àkọlé; 51:4; Owe 28:13
2 Sám. 12:13Ẹk 34:6; Sm 32:1
2 Sám. 12:13Le 20:10; Sm 103:10
2 Sám. 12:162Sa 12:22; Jon 3:8, 9
2 Sám. 12:20Rut 3:3; 2Sa 14:2
2 Sám. 12:202Sa 6:17
2 Sám. 12:222Sa 12:16; Joẹ 1:14
2 Sám. 12:22Ais 38:3, 5; Joẹ 2:13, 14; Emọ 5:15; Jon 3:8, 9
2 Sám. 12:23Onw 9:6
2 Sám. 12:23Job 30:23; Onw 3:20; Iṣe 2:29, 34; 13:36
2 Sám. 12:23Onw 9:5, 10
2 Sám. 12:242Sa 11:3
2 Sám. 12:241Kr 3:5, 9; 22:9; 28:5; Mt 1:6
2 Sám. 12:242Sa 7:12; 1Kr 29:1
2 Sám. 12:252Sa 7:4, 5; 12:1; 1Ọb 1:8
2 Sám. 12:26Di 3:11; Joṣ 13:24, 25
2 Sám. 12:26Di 23:3, 6
2 Sám. 12:262Sa 11:25; 1Kr 20:1
2 Sám. 12:272Sa 11:1
2 Sám. 12:302Sa 8:11, 12
2 Sám. 12:301Kr 20:2, 3
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
  • 29
  • 30
  • 31
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
2 Sámúẹ́lì 12:1-31

Sámúẹ́lì Kejì

12 Nítorí náà, Jèhófà rán Nátánì+ sí Dáfídì. Ó wọlé wá bá a,+ ó sì sọ pé: “Àwọn ọkùnrin méjì wà nínú ìlú kan, ọ̀kan jẹ́ ọlọ́rọ̀, èkejì sì jẹ́ aláìní. 2 Ọlọ́rọ̀ náà ní àgùntàn àti màlúù tó pọ̀ gan-an;+ 3 ṣùgbọ́n ọkùnrin aláìní náà kò ní nǹkan kan àfi abo ọ̀dọ́ àgùntàn kan tí ó rà.+ Ó ń tọ́jú rẹ̀, ó sì ń dàgbà lọ́dọ̀ òun àti àwọn ọmọ rẹ̀. Ó máa ń jẹ lára oúnjẹ díẹ̀ tí ọkùnrin náà ní, á mu látinú ife rẹ̀, àyà rẹ̀ ló sì ń sùn sí. Ó wá dà bí ọmọbìnrin fún un. 4 Nígbà tó yá, àlejò kan dé sọ́dọ̀ ọlọ́rọ̀ náà, ṣùgbọ́n kò mú lára àwọn àgùntàn àti màlúù rẹ̀ láti fi se oúnjẹ fún arìnrìn-àjò tí ó dé sọ́dọ̀ rẹ̀. Kàkà bẹ́ẹ̀, abo ọ̀dọ́ àgùntàn ọkùnrin aláìní yẹn ló lọ mú, ó sì pa á fún ọkùnrin tí ó dé sọ́dọ̀ rẹ̀.”+

5 Inú bí Dáfídì gan-an sí ọkùnrin náà, ó sì sọ fún Nátánì pé: “Bí Jèhófà ti wà láàyè,+ ikú tọ́ sí ọkùnrin tó ṣe irú èyí! 6 Ó sì yẹ kó san ìlọ́po mẹ́rin+ abo ọ̀dọ́ àgùntàn náà, nítorí ohun tó ṣe yìí àti nítorí pé kò lójú àánú.”

7 Ìgbà náà ni Nátánì sọ fún Dáfídì pé: “Ìwọ ni ọkùnrin náà! Ohun tí Jèhófà Ọlọ́run Ísírẹ́lì sọ nìyí: ‘Èmi ni mo fòróró yàn ọ́ ṣe ọba lórí Ísírẹ́lì,+ mo sì gbà ọ́ lọ́wọ́ Sọ́ọ̀lù.+ 8 Tinútinú ni mo fún ọ ní ilé ọ̀gá rẹ,+ tí mo fi àwọn ìyàwó ọ̀gá rẹ+ lé ọ lọ́wọ́, mo sì fún ọ ní ilé Ísírẹ́lì àti ilé Júdà.+ Àfi bíi pé ìyẹn ò tó, mo tún fẹ́ ṣe púpọ̀ sí i fún ọ.+ 9 Kí ló dé tí o kò fi ka ọ̀rọ̀ Jèhófà sí, tí o wá ṣe ohun tó burú lójú rẹ̀? O fi idà pa+ Ùráyà ọmọ Hétì! Lẹ́yìn náà, o sọ ìyàwó rẹ̀ di tìrẹ+ lẹ́yìn tí o ti mú kí idà àwọn ọmọ Ámónì pa á.+ 10 Wò ó, idà kò ní kúrò ní ilé rẹ láé,+ nítorí pé o kọ̀ mí, tí o sì sọ ìyàwó Ùráyà ọmọ Hétì di tìrẹ.’ 11 Ohun tí Jèhófà sọ nìyí: ‘Wò ó, màá mú kí àjálù bá ọ láti inú ilé ara rẹ;+ ojú rẹ ni màá ti gba àwọn ìyàwó rẹ,+ tí màá fi wọ́n fún ọkùnrin míì,* tí á sì bá wọn sùn ní ọ̀sán gangan.*+ 12 Bó tiẹ̀ jẹ́ pé ìkọ̀kọ̀+ ni o ti ṣe é, iwájú gbogbo Ísírẹ́lì ni màá ti ṣe ohun tí mo sọ yìí ní ọ̀sán gangan.’”*

13 Dáfídì wá sọ fún Nátánì pé: “Mo ti ṣẹ̀ sí Jèhófà.”+ Nátánì dá Dáfídì lóhùn pé: “Jèhófà, ní tirẹ̀ ti dárí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ jì ọ́.*+ O ò ní kú.+ 14 Síbẹ̀, nítorí pé ohun tí o ṣe yìí fi hàn pé o ò bọ̀wọ̀ fún Jèhófà rárá, ó dájú pé ọmọkùnrin tí obìnrin náà ṣẹ̀ṣẹ̀ bí fún ọ, yóò kú.”

15 Lẹ́yìn náà, Nátánì gba ilé rẹ̀ lọ.

Jèhófà fi àrùn kọ lu ọmọ tí ìyàwó Ùráyà bí fún Dáfídì, ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í ṣàìsàn. 16 Dáfídì bẹ Ọlọ́run tòótọ́ nítorí ọmọ náà. Dáfídì gba ààwẹ̀ tó le, ó sì máa ń sùn sórí ilẹ̀ ní alaalẹ́.+ 17 Nítorí náà, àwọn àgbààgbà ilé rẹ̀ wá sẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀, wọ́n fẹ́ gbé e dìde kúrò nílẹ̀, àmọ́ kò gbà, kò sì bá wọn jẹun. 18 Ní ọjọ́ keje, ọmọ náà kú, àmọ́ ẹ̀rù ń ba àwọn ìránṣẹ́ Dáfídì láti sọ fún un pé ọmọ náà ti kú. Wọ́n sọ pé: “A bá a sọ̀rọ̀ nígbà tí ọmọ náà ṣì wà láàyè, àmọ́ kò gbọ́ tiwa. Báwo ni a ṣe máa sọ fún un pé ọmọ náà ti kú? Ó lè lọ ṣe ohun tí á léwu gan-an.”

19 Nígbà tí Dáfídì rí i pé àwọn ìránṣẹ́ òun ń sọ̀rọ̀ kẹ́lẹ́kẹ́lẹ́ láàárín ara wọn, ó fi òye gbé e pé ọmọ náà ti kú. Dáfídì béèrè lọ́wọ́ àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ pé: “Ṣé ọmọ náà ti kú ni?” Wọ́n fèsì pé: “Ó ti kú.” 20 Torí náà, Dáfídì dìde nílẹ̀. Ó lọ wẹ̀, ó fi òróró para,+ ó pààrọ̀ aṣọ rẹ̀, ó lọ sí ilé+ Jèhófà, ó sì wólẹ̀. Lẹ́yìn náà, ó lọ sí ilé* rẹ̀, ó ní kí wọ́n gbé oúnjẹ wá fún òun, ó sì jẹun. 21 Àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé: “Kí nìdí tí o fi ṣe ohun tí o ṣe yìí? Nígbà tí ọmọ náà ṣì wà láàyè, o gbààwẹ̀, o sì ń sunkún; àmọ́ gbàrà tí ọmọ náà kú, o dìde, o sì jẹun.” 22 Ó fèsì pé: “Nígbà tí ọmọ náà ṣì wà láàyè, mo gbààwẹ̀,+ mo sì ń sunkún torí mo sọ fún ara mi pé, ‘Ta ló mọ̀ bóyá Jèhófà lè ṣojú rere sí mi, kó sì jẹ́ kí ọmọ náà yè?’+ 23 Ní báyìí tí ó ti kú, ṣé ó tún yẹ kí n máa gbààwẹ̀? Ṣé mo lè dá a pa dà ni?+ Èmi ni màá lọ bá a,+ àmọ́ kò lè wá bá mi.”+

24 Nígbà náà, Dáfídì tu Bátí-ṣébà+ ìyàwó rẹ̀ nínú. Ó wọlé lọ bá a, ó sì bá a ní àṣepọ̀. Nígbà tó yá, ó bí ọmọkùnrin kan, ó pe orúkọ rẹ̀ ní Sólómọ́nì.*+ Jèhófà sì nífẹ̀ẹ́ rẹ̀,+ 25 ó rán wòlíì Nátánì+ kí ó pe orúkọ rẹ̀ ní Jedidáyà,* nítorí Jèhófà.

26 Jóábù ń bá Rábà+ ìlú àwọn ọmọ Ámónì+ jà nìṣó, ó sì gba ìlú ọba.*+ 27 Nítorí náà, Jóábù rán àwọn òjíṣẹ́ sí Dáfídì, ó sọ pé: “Mo ti bá Rábà+ jà, mo sì ti gba ìlú omi.* 28 Ní báyìí, kó àwọn ọmọ ogun tó ṣẹ́ kù jọ, kí o dó ti ìlú náà, kí o sì gbà á. Àìjẹ́ bẹ́ẹ̀, èmi ni màá gba ìlú náà, wọ́n á sì máa yìn mí pé èmi ni mo gbà á.”*

29 Nítorí náà, Dáfídì kó gbogbo àwọn ọmọ ogun jọ, ó lọ sí Rábà, ó bá a jà, ó sì gbà á. 30 Nígbà náà, ó mú adé Málíkámù kúrò ní orí rẹ̀. Ìwọ̀n adé náà jẹ́ tálẹ́ńtì* wúrà kan, pẹ̀lú àwọn òkúta iyebíye, a sì fi dé Dáfídì lórí. Ó tún kó ẹrù+ tó pọ̀ gan-an látinú ìlú náà.+ 31 Ó kó àwọn èèyàn inú rẹ̀, ó fi wọ́n sídìí iṣẹ́ pé kí wọ́n máa fi ayùn rẹ́ òkúta, kí wọ́n máa fi àwọn ohun èlò onírin mímú àti àáké ṣiṣẹ́, kí wọ́n sì máa ṣe bíríkì. Ohun tó ṣe sí gbogbo àwọn ìlú àwọn ọmọ Ámónì nìyẹn. Níkẹyìn, Dáfídì àti gbogbo àwọn ọmọ ogun náà pa dà sí Jerúsálẹ́mù.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́