ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 122
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Sáàmù

      • Àdúrà fún àlàáfíà Jerúsálẹ́mù

        • Ayọ̀ tó wà nínú lílọ sí ilé Jèhófà (1)

        • Ìlú tó so pọ̀ mọ́ra (3)

Sáàmù 122:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 6:15; Sm 27:4; 42:4; 84:10

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Ìjọba,

    5/2002, ojú ìwé 3

    Jí!,

    10/22/1997, ojú ìwé 31

Sáàmù 122:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Kr 6:6; Sm 84:7; 100:4

Sáàmù 122:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 5:9

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    12/15/2014, ojú ìwé 24

    9/1/2006, ojú ìwé 15

Sáàmù 122:4

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    “Jáà” ni ìkékúrú Jèhófà.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 23:17; Di 12:5, 6

Sáàmù 122:5

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 17:8, 9; 2Kr 19:8
  • +2Sa 7:16; 1Ọb 10:18; 1Kr 29:23

Sáàmù 122:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 51:18

Sáàmù 122:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “àwọn odi ààbò rẹ.”

Sáàmù 122:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Kr 29:3; Sm 26:8; 69:9

Àwọn míì

Sm 122:12Sa 6:15; Sm 27:4; 42:4; 84:10
Sm 122:22Kr 6:6; Sm 84:7; 100:4
Sm 122:32Sa 5:9
Sm 122:4Ẹk 23:17; Di 12:5, 6
Sm 122:5Di 17:8, 9; 2Kr 19:8
Sm 122:52Sa 7:16; 1Ọb 10:18; 1Kr 29:23
Sm 122:6Sm 51:18
Sm 122:91Kr 29:3; Sm 26:8; 69:9
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Sáàmù 122:1-9

Sáàmù

Orin Ìgòkè. Ti Dáfídì.

122 Mo yọ̀ nígbà tí wọ́n sọ fún mi pé:

“Jẹ́ ká lọ sí ilé Jèhófà.”+

2 Ní báyìí, ẹsẹ̀ wa dúró

Ní àwọn ẹnubodè rẹ, ìwọ Jerúsálẹ́mù.+

3 A kọ́ Jerúsálẹ́mù bí ìlú,

Ó so pọ̀ mọ́ra.+

4 Àwọn ẹ̀yà ti lọ síbẹ̀,

Àwọn ẹ̀yà Jáà,*

Kí wọ́n lè fi ọpẹ́ fún orúkọ Jèhófà,

Gẹ́gẹ́ bí ìrántí fún Ísírẹ́lì.+

5 Nítorí ibẹ̀ la gbé àwọn ìtẹ́ ìdájọ́ kalẹ̀ sí,+

Àwọn ìtẹ́ ilé Dáfídì.+

6 Ẹ gbàdúrà pé kí Jerúsálẹ́mù ní àlàáfíà.+

Àwọn tó nífẹ̀ẹ́ rẹ yóò wà láìséwu, ìwọ ìlú.

7 Kí àlàáfíà máa wà nínú àwọn odi rẹ,*

Kí ààbò sì wà nínú àwọn ilé gogoro rẹ tó láàbò.

8 Nítorí àwọn arákùnrin mi àti àwọn ọ̀rẹ́ mi, màá sọ pé:

“Kí àlàáfíà wà nínú rẹ.”

9 Nítorí ilé Jèhófà Ọlọ́run wa,+

Màá wá ire fún ọ.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́