ONÍWÀÁSÙ
OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ
1
2
Àgbéyẹ̀wò àwọn ohun tí Sólómọ́nì ṣe (1-11)
Ó níbi tí ọgbọ́n èèyàn wúlò dé (12-16)
Asán tó wà nínú iṣẹ́ àṣekára (17-23)
Máa jẹ, máa mu, kí o sì gbádùn iṣẹ́ rẹ (24-26)
3
Ohun gbogbo ni àkókò wà fún (1-8)
Ká gbádùn ayé, ẹ̀bùn Ọlọ́run ni (9-15)
Òdodo ni Ọlọ́run fi ń ṣe ìdájọ́ gbogbo èèyàn (16, 17)
Bí èèyàn ṣe ń kú náà ni ẹranko ń kú (18-22)
4
Ìnilára burú ju ikú lọ (1-3)
Ojú tó yẹ ká fi wo iṣẹ́ (4-6)
Iyì ọ̀rẹ́ (7-12)
Ìgbésí ayé alákòóso lè jẹ́ asán (13-16)
5
Wá síwájú Ọlọ́run pẹ̀lú ìbẹ̀rù tó yẹ (1-7)
Àwọn tó ga ju àwọn tó wà nípò gíga ń ṣọ́ wọn (8, 9)
Asán tó wà nínú ọrọ̀ (10-20)
6
7
Orúkọ rere àti ọjọ́ ikú (1-4)
Ìbáwí tí ọlọ́gbọ́n fúnni (5-7)
Òpin nǹkan sàn ju ìbẹ̀rẹ̀ rẹ̀ lọ (8-10)
Àǹfààní ọgbọ́n (11, 12)
Ọjọ́ rere àti ọjọ́ burúkú (13-15)
Yẹra fún àṣejù (16-22)
Àwọn ohun tí akónijọ kíyè sí (23-29)
8
9
Ohun kan náà ló ń gbẹ̀yìn gbogbo wọn (1-3)
Gbádùn ayé rẹ bí ikú tiẹ̀ máa dé (4-12)
Kì í ṣe gbogbo ìgbà ni àwọn èèyàn máa ń mọyì ọgbọ́n (13-18)
10
Ìwà òmùgọ̀ díẹ̀ ń ba ọgbọ́n jẹ́ (1)
Ewu tó wà nínú àìmọṣẹ́ (2-11)
Ohun búburú tó máa ń ṣẹlẹ̀ sí àwọn òmùgọ̀ (12-15)
Ìwà òmùgọ̀ àwọn alákòóso (16-20)
11
12