ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • w94 12/15 ojú ìwé 31
  • Atọ́ka Àwọn Kókó-Ẹ̀kọ́ Fún Ilé-Ìṣọ́nà 1994

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Atọ́ka Àwọn Kókó-Ẹ̀kọ́ Fún Ilé-Ìṣọ́nà 1994
  • Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1994
  • Ìsọ̀rí
  • ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JEHOFA
  • ÀWỌN ÌTÀN ÌGBÉSÍ-AYÉ
  • ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN
  • BIBELI
  • ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
  • ÌGBÉSÍ-AYÉ ÀTI ÀWỌN ÀNÍMỌ́ KRISTIAN
  • JEHOFA
  • JESU KRISTI
  • LÁJORÍ ÀWỌN Ọ̀RỌ̀ ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
  • Ọ̀KANKÒJỌ̀KAN
Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1994
w94 12/15 ojú ìwé 31

Atọ́ka Àwọn Kókó-Ẹ̀kọ́ Fún Ilé-Ìṣọ́nà 1994

Tí ń tọ́ka ọjọ́ ìtẹ̀jáde nínú èyí tí ọ̀rọ̀-ẹ̀kọ́ farahàn

ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JEHOFA

Àgbègbè Tí Kò fi Bẹ́ẹ̀ Lajú ní Alaska, 4/15

Alákòókò Kan Náà fún Ọdún Mẹ́wàá! 4/1

Àpéjọpọ̀ Àgbègbè “Ẹ̀kọ́ Àtọ̀runwá,” 1/15, 7/1, 8/15

Àpéjọpọ̀ Àgbègbè “Ìbẹ̀rù Ọlọrun,” 5/1

Àwọn Aṣáájú-Ọ̀nà Ń Fìbùkún Jíǹkí Ẹni Wọ́n Sì Ń Rí I Gbà, 1/15

“Àwọn Ẹlẹ́rìí Jehofa Dáàbòbò Mí!” 5/15

‘Àwọn Ìṣe Rẹ̀ Ń Tọ̀ Ọ́ Lẹ́yìn’ (G. Gangas), 12/1

Àwọn Olùwá-Ibi-Ìsádi Láyọ̀ Láti Máa Ṣiṣẹ́sin Ọlọrun (Central African Republic), 10/15

Àwọn Ọ̀dọ́ tí Wọ́n ‘Gbẹ́kẹ̀lé Jehofa,’ 1/1

Bahamas, 3/15

Colombia, 7/15

Èéṣe tí Àwọn Ẹlẹ́rìí fi Ń Ṣèbẹ̀wò Lemọ́lemọ́? 8/15

Èmi ti Pa Ìgbàgbọ́ Mọ́” (B. Inconditi), 7/1

Ethiopia, 8/15

Ẹgbẹ́ Awo Tàbí Òjíṣẹ́ Ọlọrun? 2/15

“Ẹja Pípa” Nínú Àwọn Omi Fiji, 6/15

Fífi Ìmọrírì Wo “Ilé Ọlọrun” (Beteli), 6/15

Ìgbàgbọ́ Onígboyà ti Àwọn Ará ní Rwanda, 11/1

Ìkẹ́kọ̀ọ́yege Gileadi, 6/1, 12/1

Ìlà-Oòrùn Pàdé Ìwọ̀-Oòrùn, 1/1

Ìlú Aláààrẹ ti Philippines, 1/15

Malawi, 5/15

Nigeria, 9/15

Ọ̀ràn Ìbànújẹ́ ní Rwanda, 12/15

Poland, 11/15

Ṣíṣèrànwọ́ fún Àwọn Onígbàgbọ́ ní Bosnia, 11/1

Thailand, 5/15

ÀWỌN ÌTÀN ÌGBÉSÍ-AYÉ

Aṣálẹ̀ kan Di Ilẹ̀ Ẹlẹ́tùlójú (A. Melin), 10/1

A ti Wá Ìjọba Náà Lákọ̀ọ́kọ́ (O. Springate), 2/1

Ìgbésí-Ayé Dídọ́ṣọ̀, Elérè-Ẹ̀san, Nínú Iṣẹ́-Ìsìn Jehofa (L. Kallio), 4/1

Mo Láyọ̀ Ninu Ojúlówó Ẹgbẹ́-Àwọn-Ará Kárí-Ayé (W. Davis), 9/1

Mo Rí Ìṣúra tí Ìníyelórí Rẹ̀ Tayọlọ́lá (F. Widdowson), 1/1

Ọlọrun náà tí Kò Lè Ṣèké Tì Mí Lẹ́yìn (M. Willis), 5/1

Ọ̀nà Ìgbésí-Ayé kan tí Ó Ní Ète Nínú (M. Wieland), 12/1

‘Ọwọ́ Jehofa’ Nínú Ìgbésí-Ayé Mi (L. Thompson), 3/1

Ṣíṣiṣẹ́sìn Pẹ̀lú Ètò-Àjọ tí Ń Tẹ̀síwájú Jùlọ (R. Hatzfeld), 8/1

Wọ́n Fi Àpẹẹrẹ Lélẹ̀ fún Wa (C. Zanker), 6/1

ÀWỌN OLÙPÒKÌKÍ ÌJỌBA RÒYÌN

1/1, 2/1, 3/1, 4/1, 5/1, 6/1, 8/1, 9/1, 10/1

BIBELI

Bibeli Lédè Goth, 5/15

‘Ewé Ìwé Kanṣoṣo Lè Jáwọ Inú Òkùnkùn Lọ Bí Ìràwọ̀,’ 5/15

Ìníyelórí Rẹ̀ Gidi, 10/1

Ìwé kan tí A Níláti Kà, 5/15

Ìwọ Ha Mọyì Bibeli Bí? 5/15

Ó Yẹ Kí A Lóye Rẹ̀, 10/1

ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ

Àwọn ọmọ-ogun Saulu tí wọ́n jẹ ẹran tẹ̀jẹ̀tẹ̀jẹ̀, 4/15

Déètì fún “ìgbà mẹ́ta àti ààbọ̀” (Ìfi 11:3), 8/1

“Ẹ̀ṣẹ̀ ba ní ẹnu ọ̀nà” (Gen 4:7), 2/1

Gbólóhùn náà “tajúkán rí,” 10/15

Jesu “gbòǹgbò” Jesse àti Dafidi, 8/15

Ó ha yẹ láti gba omi-abẹ́rẹ́ albumin tí ó ti inú ẹ̀jẹ̀ wá? 10/1

“Ọmọdékùnrin aláìníbaba” ha fi ìdàníyàn tí ó dínkù fún àwọn ọmọdébìnrin hàn bí? 1/15

Pípẹjọ́ fún ìwọkogbèsè, 9/15

ÌGBÉSÍ-AYÉ ÀTI ÀWỌN ÀNÍMỌ́ KRISTIAN

Àkójọ-Ìwé ti Ìṣàkóso Ọlọrun, 11/1

Àyẹ̀wò Ìlera, 12/15

Báwo Ni Ìwọ Ṣe Ń Yanjú Aáwọ̀? 7/15

Buyì fún Àwọn Ẹlòmíràn Nígbà Tí O Bá Ń Fún Wọn Nímọ̀ràn, 2/1

Èéṣe tí A Fi Níláti Máa Dáríjini? 9/15

Fífi Ìfẹ́ Kristian Hàn sí Àwọn Àgbàlagbà, 8/1

Ìdákẹ́kọ̀ọ́, 6/15

Ìdíje Ha Ni Kọ́kọ́rọ́ náà sí Àṣeyọrísírere Bí? 3/1

Ìkálọ́wọ́kò Ha Ń Mú Ọ Rẹ̀wẹ̀sì Bí? 9/1

Ìkanisí​—⁠Olórí Àìní Ẹ̀dá Ènìyàn, 12/1

Ìwọ Ha Ń Ṣe Ìfẹ́-Inú Ọlọrun Bí? 3/1

Kíkojú Àárò Ilé, 5/15

Mọrírì Iṣẹ́-Ìsìn Mímọ́ Ọlọ́wọ̀ Rẹ, 9/1

Olè Jíjà Ha Ni Nítòótọ́ Bí? 4/15

Orísun Ìgboyà tí Kìí Ṣákìí, 9/15

Owó-Orí, 11/15

Pípa Ìṣọ̀kan Mọ́ Láàárín Àwọn Alàgbà àti Ìránṣẹ́ Iṣẹ́-Òjíṣẹ́, 8/15

Ríran Ọmọ Rẹ Lọ́wọ́ Lati Yan Jehofa, 10/1

Sùúrù, 5/15

Ṣọ́ra fún Fífọ́nnu, 9/1

Takété Nígbà Tí Ewu Bá Fẹjúmọ́ Ọ, 2/15

Wọ́n Pinnu Láti Ṣiṣẹ́sin Jehofa! 4/15

JEHOFA

Àkọlé tí Ó Ní Ìtumọ̀ Àrà-Ọ̀tọ̀, 8/15

Kíkẹ́kọ̀ọ́ Lati Ọ̀dọ̀ Atóbilọ́lá Olùkọ́ni Wa, 9/15

JESU KRISTI

Jesu Ha Ní Ìgbàgbọ́ Nínú Ọlọrun Bí? 10/15

O Ha Níláti Gbàdúrà sí Jesu Bí? 12/15

“Oluwa”​—⁠Báwo àti Nígbà Wo? 6/1

LÁJORÍ ÀWỌN Ọ̀RỌ̀ ÌKẸ́KỌ̀Ọ́

A Níláti Kọ́kọ́ Wàásù Ìhìnrere Yìí, 8/15

Àríyànjiyàn Jehofa Pẹ̀lú Àwọn Orílẹ̀-Èdè, 3/1

Awọn Ìránṣẹ́ Ọlọrun​—⁠Awọn Ènìyàn Aláyọ̀ tí Wọ́n Wà Létòlétò, 10/1

Àwọn Olùpòkìkí Ìjọba Jẹ́ Aláápọn ní Gbogbo Ilẹ̀-Ayé, 5/1

Àwọn Olùṣọ́-Àgùtàn àti Àwọn Àgùtàn Nínú Ìṣàkóso Ọlọrun, 1/15

Bí Ó Tilẹ̀ Jẹ́ Pé Erùpẹ̀ Ni Wá, Ẹ Jẹ́ Kí A Máa Tẹ̀síwájú! 9/1

Èrè Jobu​—⁠Orísun Kan Fún Ìrètí, 11/15

Ẹ̀kọ́ Arannilọ́wọ́ fún Àwọn Àkókò Lílekoko Wa, 4/15

Ẹ̀kọ́ Àtọ̀runwá ní Ìdojú Ìjà Kọ Ẹ̀kọ́ Àwọn Ẹ̀mí Èṣù, 4/1

Ẹ̀kọ́ Àtọ̀runwá Ṣẹ́gun, 2/1

Ẹ Kó Gbogbo Àníyàn Yín Lé Jehofa, 11/15

Ẹ Kọrin Ìyìn sí Jehofa, 5/1

Ẹ Máa Ṣe Ìpolongo Ní Gbangba sí Orúkọ Jehofa, 9/15

Ẹ Máa Yọ̀ Ninu Jehofa! 9/1

Ẹ Mú Awọn Wòlíì Ọlọrun Gẹ́gẹ́ Bí Àpẹẹrẹ Àwòṣe, 9/15

Ẹ Mú Ìfòyebánilò Dàgbà, 8/1

Ẹ Ní Ìyọ́nú Oníjẹ̀lẹ́ńkẹ́, 11/1

Ẹrù-Iṣẹ́ Ń Bá Mímọ Ìsìn tí Ó Tọ̀nà Rìn, 6/1

‘Ẹ Yan Àwọn Ọ̀rẹ́ Nípasẹ̀ Ọrọ̀ Àìṣòdodo,’ 12/1

Ẹ̀yin Èwe​—⁠Ẹ̀kọ́ Ta Ni Ẹ Ń Kọbiara Sí? 5/15

Ẹ̀yin Òbí, Àwọn Ọmọ Yín Nílò Àfiyèsí Àrà-Ọ̀tọ̀, 5/15

Fi Jehofa Ṣe Ààbò-Ìsádi, 1/1

Fífayọ̀ Tẹríba fún Ọlá-Àṣẹ, 7/1

Fífi Ìfẹ́ Ṣe Olùṣọ́ Àgùtàn Agbo Ọlọrun, 10/1

Gbádùn Àwọn Àǹfààní Ẹ̀kọ́ Àtọ̀runwá, 2/1

Gbígbógunti Ìwàmú Ẹ̀ṣẹ̀ Lórí Ẹran-Ara Ẹlẹ́ṣẹ̀, 6/15

Ìdájọ́ Jehofa Lòdìsí Àwọn Olùkọ́ni Èké, 3/1

Ìdí Tí Àwọn Ẹlẹ́rìí Jehofa Fi Ń Báa Nìṣó Ní Ṣíṣọ́nà, 5/1

Ilé-Ìṣọ́nà àti Jí!​—⁠Àwọn Àkànṣe Ìwé-Ìròyìn Òtítọ́ Bíbọ́sákòókò, 1/1

Ipò Pàtàkì tí Ó Yẹ Ìjọsìn Jehofa Nínú Ìgbésí-Ayé Wa, 12/1

Ìṣùpọ̀-Èso​—⁠Dídára àti Búburú, 3/1

Ìwọ Ha Ń Dáríjini Bí Jehofa ti Ń Ṣe Bí? 10/15

Ìwọ Ha Ń Gbéjàko Ẹ̀mí Ayé Bí? 4/1

Ìwọ Ha Ń Kọ́ni Bí Jesu Ti Ṣe Bí? 10/15

Ìwọ Ha Ti Rí Ìsìn tí Ó Tọ̀nà Bí? 6/1

Jehofa​—⁠Bàbá Wa Oníyọ̀ọ́nú Lọ́nà Jẹ̀lẹ́ńkẹ́, 11/1

Jehofa Lè Sọ Ọ́ Di Alágbára, 12/15

Jehofa Ń Fòyebánilò! 8/1

Jehofa Ń Ṣàkóso​—⁠Nípasẹ̀ Ìṣàkóso Ọlọrun, 1/15

Jehofa​—⁠Ọlọrun Ète, 3/15

Jíjẹ́rìí fún “Gbogbo Awọn Orílẹ̀-Èdè,” 8/15

Jobu Lo Ìfaradà​—⁠Àwa Pẹ̀lú Lè Ṣe Bẹ́ẹ̀! 11/15

‘Kí Ni Yóò Ṣe Àmì Wíwàníhìn-⁠ín Rẹ?’ 2/15

Lórí Tábìlì Wo Ni Ìwọ ti Ń Jẹun? 7/1

Mú Kí Ìgbéyàwó Rẹ Jẹ́ Ìsopọ̀ Wíwàpẹ́títí, 7/15

Ní Ìgbẹ́kẹ̀lé Pé Jehofa Yóò Mú Ète Rẹ̀ Ṣẹ, 3/15

Ojú-Ìwòye Kristian Nípa Ọlá-Àṣẹ, 7/1

Rìn Ní Ìbámu Pẹ̀lú Ìtọ́ni Ọlọrun, 4/15

Sọ Ẹ̀kọ́ Afúnninílera Di Ọ̀nà Ìgbésí-Ayé Rẹ, 6/15

“Sọ Fún Wa, Nígbà Wo Ni Nǹkan Wọ̀nyí Yóò Ṣẹ?” 2/15

Ṣiṣẹ́ Kára fún Ìgbàlà Agbo-Ilé Rẹ, 7/15

Wọ́n Wà Ní Ìṣọ̀kan Nínú Ìdè Ìfẹ́ Pípé, 12/15

Ọ̀KANKÒJỌ̀KAN

Abrahamu​—⁠A Sin Ín Síhìn-⁠ín, Síbẹ̀ Ó Wàláàyè Kẹ̀? 6/15

Àìgbàgbọ́ Nínú Wíwà Ọlọrun, 12/1

A San Èrè-Ẹ̀san fún Wọn fún Rírìn Láìlẹ́bi (Sekariah, Elisabeti), 7/15

Àwọn Ẹgbẹ́ Awo​—⁠Kí Ni Wọ́n Jẹ́? 2/15

Àwọn Ẹ̀mí Búburú, 2/1

Àwọn Ìwé Ìtàn Fífanimọ́ra ti Josephus, 3/15

Àwọn Òkú Ha Lè Pa Àwọn Alààyè Lára Bí? 10/15

Àwọn Òkú Ha Ń Rí Wa Bí? 11/15

Àwọn Olólùfẹ́ tí Wọ́n Ti Kú​—⁠A Ha Tún Lè Rí Wọn Bí? 6/15

Ayé Dídára Jù Kan​—⁠Àlá kan Lásán Ha Ni Bí? 4/1

Àyẹ̀wò Ìlera, 12/15

Ayẹyẹ Ọjọ́-Ìbí, 7/15

Báwo Ni Ènìyàn Ṣe Lè Jẹ́ Ní Àwòrán Ọlọrun? 4/1

‘Bọ́ Ẹnu, Kìí Ṣe Ẹsẹ̀’ (àṣà ìsìnkú àtọwọ́dọ́wọ́ Africa), 3/15

Ẹfolúṣọ̀n Ń Jẹ́jọ́, 9/1

Ìbẹ̀rù Gbá Aráyé Mú, 7/15

Ibojì Peteru​—⁠Ní Vatican Kẹ̀? 10/15

Ìdánìkanwà, 9/15

Ìgbàgbọ́ Aláìjampata ti Ìgbàsókè-Ọ̀run, 2/15

Ìgbìmọ̀ Aṣòfin Gíga Jùlọ ti Àwọn Ìsìn Àgbáyé, 2/1

Ìjìyà Ẹ̀dá Ènìyàn​—⁠Ìdí Tí Ọlọrun Fi Fàyègbà Á, 11/1

Ìmọ̀-Ìjìnlẹ̀, Ìsìn, ati Wíwá Òtítọ́ Kiri, 9/1

Ìrètí fún Àwọn Afọ́jú, 8/15

Ìrọ̀dẹ̀dẹ̀ Ewu Agbára Átọ́míìkì, 8/1

Ìsìn Ha Ń Kúnjú Àwọn Àìní Rẹ Bí? 5/1

Ìṣẹ̀lẹ̀ Ìbànújẹ́ ní Rwanda, 12/15

Ìtọ́sọ́nà Tí Ó Ṣeé Gbáralé, 4/15

Ìwákiri fún Ìsìn Tí Ó Tọ̀nà, 6/1

Jehofa Ṣe Ojúrere sí I Lọ́nà Gíga (Maria), 11/15

Kàlẹ́ńdà Àwọn Ju, 7/15

Keresimesi​—⁠Ó Ha Bá Ìsìn Kristian Mú Nítòótọ́ Bí? 12/15

Kí Ni Ó Ti Ṣẹlẹ̀ sí Ọlá-Àṣẹ? 7/1

Kò Dàgbà Jù Láti Ṣiṣẹ́sin Jehofa (Anna), 5/15

“Kọ̀ Láti Gba Àwọn Ìtàn Èké,” 4/1

Lílajú sí Ìhìnrere, 8/15

Níbo Ni Àwọn Òkú Wà? 11/15

Ogun Yóò Ha Dópin Láé Bí? 1/15

Ó Rí Ìmúṣẹ Ìfẹ́-Ọkàn Rẹ̀ (Simeoni), 3/15

Oúnjẹ Alẹ́ Oluwa​—⁠Báwo Ni A Ṣe Níláti Ṣe É Lemọ́lemọ́ Tó? 3/15

Ṣọ́ọ̀ṣì kan tí Ìyapa Wà​—⁠Ó Ha Lè Làájá Bí? 7/1

William Whiston—Aládàámọ̀ Tàbí Ọ̀mọ̀wèé Akẹ́kọ̀ọ́jinlẹ̀ Aláìlábòsí? 3/15

“Wọ́n Mọ Ohùn Rẹ̀,” 7/15

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́