Atọ́ka Àwọn Àkòrí Inú Ilé Ìṣọ́ 2004
Ó ń tọ́ka sí Ilé Ìṣọ́ tí àpilẹ̀kọ kọ̀ọ̀kan ti jáde
ÀWỌN ẸLẸ́RÌÍ JÈHÓFÀ
Àpéjọ Àgbègbè “Ẹ Fi Ògo fún Ọlọ́run,” 1/15
“Àwọn Ẹni Ìgbàgbé” Ti Wá Di Ẹni Ìrántí, 9/1
Àwọn Ọmọ Ìbílẹ̀ Mẹ́síkò, 8/15
Àwọn Ọ̀rẹ́ Ọlọ́run Làwọn Erékùṣù Tonga, 12/15
Àwọn Tó Dúró Ṣinṣin Tí Wọn Ò Bọ́hùn (Poland), 10/15
Ayẹyẹ Ìkẹ́kọ̀ọ́yege ní Ilé Ẹ̀kọ́ Gílíádì, 6/15, 12/15
Ayọ̀ Tó Wà Nínú Ṣíṣètọrẹ, 11/1
Ẹ̀rí Ọkàn Tó Dára (fóònù alágbèérìn tí wọ́n dá padà), 2/1
‘Ẹ Wá, Kí Ẹ sì Ràn Wá Lọ́wọ́’ (Bolivia), 6/1
Kì Í Ṣe Eré Lásán (àwọn ọmọdé), 10/1
Lẹ́tà Tí Alejandra Kọ (Mẹ́síkò), 10/1
Liberia, 4/1
Lílọ Wàásù Fáwọn Èèyàn Níbi Iṣẹ́ Wọn, 4/1
Ó Bá Àwọn Ọmọ Kíláàsì Rẹ̀ Sọ̀rọ̀ Nípa Ẹ̀sìn Rẹ̀ (Poland), 10/1
‘O Kọ́ Wa Láti Ṣe Ohun Tó Bá Ìgbàgbọ́ Rẹ̀ Mu’ (Ítálì), 6/15
Ṣíṣe Oore Fáwọn Èèyàn Lákòókò Ìṣòro, 6/1
Wíwàásù Láìjẹ́-Bí-Àṣà Fáwọn Tó Ń Sọ Èdè Gẹ̀ẹ́sì ní Mẹ́síkò, 4/15
Wọ́n Ń Gbèrú, 3/1
Wọ́n Pé Jọ sí ‘Agbedeméjì Ayé’ (Erékùṣù Easter), 2/15
BÍBÉLÌ
Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Jẹ́nẹ́sísì—Apá Kìíní, 1/1
Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Jẹ́nẹ́sísì—Apá Kejì, 1/15
Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Ẹ́kísódù, 3/15
Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Léfítíkù, 5/15
Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Númérì, 8/1
Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Diutarónómì, 9/15
Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Jóṣúà, 12/1
Bíbélì Elédè Púpọ̀ ti Complutensian, 4/15
Bíbélì Tí Ò “Láfiwé” (Ìtumọ̀ Ayé Tuntun lédè Gẹ̀ẹ́sì), 12/1
Ìṣúra Chester Beatty, 9/15
Onígboyà “Tó Lọ Káàkiri Nítorí Ìhìn Rere” (G. Borrow), 8/15
ÌBÉÈRÈ LÁTI ỌWỌ́ ÀWỌN ÒǸKÀWÉ
Àjẹkì, 11/1
“Aláìgbàgbọ́” (2Kọ 6:14), 7/1
Àwọn ẹ̀mí èṣù nígbà Ẹgbẹ̀rún Ọdún, 11/15
Báwo la ṣe lè kó ẹ̀dùn ọkàn bá ẹ̀mí mímọ́? (Ef 4:30), 5/15
Báwo ni Hánámélì ṣe wá ta pápá fún Jeremáyà? (Jer 32:7), 3/1
‘Ẹ máa wínni láìretí ohunkóhun padà’ (Lk 6:35), 10/15
Ibo ni ẹyẹ àdàbà ti rí ewé ólífì? (Jẹ 8:11), 2/15
Ìdí tí Ọlọ́run fi fàyè gba àwọn ọkùnrin Ísírẹ́lì láti fẹ́ obìnrin tí wọ́n mú lóǹdè, 9/15
Ìdí tí Jésù fi jẹ́ kí Tọ́másì fọwọ́ kan òun àmọ́ tí ò gbà kí Màríà Magidalénì ṣe bẹ́ẹ̀, 12/1
“Ìfẹ́ pípé” (1Jo 4:18), 10/1
Ìpín kékeré tá a mú jáde látinú ẹ̀jẹ̀, 6/15
Kí ló ṣẹlẹ̀, ta sì ni ẹ̀mí rẹ̀ wà nínú ewu? (Ẹk 4:24-26), 3/15
Kí nìdí tí Júdà fi bá obìnrin tó kà sí aṣẹ́wó lò pọ̀? (Jẹ 38:15), 1/15
Kí nìdí tí Míkálì fi ní ère Tẹ́ráfímù? (1Sa 19:13), 6/1
Ohun tí ọdún Júbílì ṣàpẹẹrẹ, 7/15
‘Sátánì ti já bọ́ láti ọ̀run’ (Lk 10:18), 8/1
Ṣé erékùṣù Málítà ni ọkọ̀ ti ri Pọ́ọ̀lù? 8/15
Ṣé ẹgbẹ̀rún mẹ́tàlélógún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ló ṣubú ni àbí ẹgbẹ̀rún mẹ́rìnlélógún? (1Kọ 10:8; Nu 25:9), 4/1
Ṣe iye gidi ni ọ̀kẹ́ méje ó lé ẹgbàajì? 9/1
Ṣé ràkúnmí gidi àti abẹ́rẹ́ ìránṣọ ni? (Mt 19:24; Mk 10:25; Lk 18:25), 5/15
ÌGBÉSÍ AYÉ ÀTI ÀNÍMỌ́ KRISTẸNI
Ábúráhámù àti Sárà—O Lè Fara Wé Ìgbàgbọ́ Wọn! 5/15
“Afọgbọ́nhùwà Yóò Fi Ìmọ̀ Hùwà” (Òwe orí 13), 7/15
“Àgọ́ Àwọn Adúróṣánṣán Yóò Gbilẹ̀” (Òwe orí 14), 11/15
Àwọn Ohun Tó Ò Ń Lé Nípa Tẹ̀mí, 7/15
Bá A Ṣe Ń Fi Hàn Pé A Nífẹ̀ẹ́ Ọlọ́run, 3/1
Ẹ̀mí Ìdúródeni, 10/1
Ẹ̀yin Ọ̀dọ́—Ẹ Jẹ́ Káwọn Òbí Yín Ràn Yín Lọ́wọ́ Kẹ́ Ẹ Lè Dáàbò Bo Ọkàn Yín! 10/15
Ìlànà Ta Ló Yẹ Kó O Tẹ̀ Lé Láti Ṣe Ohun Tó Tọ́? 12/1
Ìtùnú fún Àwọn Tó Wà Nínú Ìpọ́njú, 2/15
“Ja Ìjà Àtàtà ti Ìgbàgbọ́,” 2/15
Ǹjẹ́ Àìdá-sí-Ìṣèlú Dí Ìfẹ́ Kristẹni Lọ́wọ́? 5/1
Ogún Tó Yẹ Kéèyàn Fi Sílẹ̀ fún Àwọn Ọmọ, 9/1
Ohun Tó O Lè Ṣe Nígbà Tí Nǹkan Bá Tojú Sú Ọ, 9/1
O Lè Borí Iyèméjì, 2/1
Ọmọ Títọ́, 6/15
Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa, 3/15
Ṣé Ìṣòro Tó Dé Bá Ọ Ló Ń Darí Ìgbésí Ayé Rẹ? 6/1
Tẹjú Mọ́ Èrè Náà, 4/1
ÌTÀN ÌGBÉSÍ AYÉ
A Bù Kún Wa Jìngbìnnì Nítorí Pé A ní Ẹ̀mí Míṣọ́nnárì (T. Cooke), 1/1
Àwọn Nǹkan Díẹ̀ Tá A Yááfì Jẹ́ Ká Rí Ọ̀pọ̀ Ìbùkún (G. àti A. Aljian), 4/1
Ẹ̀kọ́ Tí Mo Ti Ń Kọ Láti Kékeré (H. Gluyas), 10/1
Ìgbà Tí Mo Fọ́jú Lójú Mi Tó Là! (E. Hauser), 5/1
Ìṣàkóso Ọlọ́run Làwá Fara Mọ́ (M. Žobrák), 11/1
Mo Gbé Ìgbésí Ayé Aláyọ̀ Láìfi Ìrora Ọkàn Pè (A. Hyde), 7/1
Mo Gbọ́kàn Lé Jèhófà Pé Á Bójú Tó Mi (A. Denz Turpin), 12/1
Mo Jáde Látinú Àjàalẹ̀ Lọ sí Switzerland (L. Walther), 6/1
Mo Ń Gbádùn Inú Rere àti Àbójútó Jèhófà (F. King), 2/1
Níní Ìtẹ́lọ́rùn Tí Ọlọ́run Ń Fúnni Ti Mẹ́sẹ̀ Mi Dúró (I. Osueke), 3/1
Okun Jèhófà La Gbára Lé (E. Haffner), 8/1
Yíyọ̀ǹda Ara Wa Ti Jẹ́ Kí Ayé Wa Dára Kó sì Láyọ̀ (M. àti R. Szumiga), 9/1
JÈHÓFÀ
“Àwọn Iṣẹ́ Rẹ Mà Pọ̀ O!” 11/15
Ẹ̀mí Ìrẹ̀lẹ̀, 11/1
‘Kí Ìfẹ́ Rẹ Ṣẹ Lórí Ilẹ̀ Ayé,’ 4/15
Ǹjẹ́ Ọlọ́run Tiẹ̀ Bìkítà Nípa Wa? 1/1
O Lè Múnú Ọlọ́run Dùn, 5/15
Ọlọ́run Bìkítà fún Ọ Lóòótọ́, 7/1
JÉSÙ KRISTI
Àwọn Iṣẹ́ Ìyanu Rẹ̀—Ṣóòótọ́ Ni Àbí Ìtàn Àròsọ? 7/15
Ìṣẹ̀lẹ̀ Mánigbàgbé Kan, 12/15
KÀLẸ́ŃDÀ
“Àwọn Igi Jèhófà Ní Ìtẹ́lọ́rùn,” 1/15
“Àwọn Iṣẹ́ Rẹ Mà Pọ̀ O!” 11/15
‘Àwọn Odò Pàtẹ́wọ́,’ 5/15
‘Ìgbà Ẹ̀rùn àti Ìgbà Òtútù Kì Yóò Kásẹ̀ Nílẹ̀ Láé,’ 7/15
‘Ìwọ Ní Ọlá Ńlá Ju Àwọn Òkè Ńlá Lọ,’ 3/15
“Ọ̀pọ̀ Jaburata Ọlá Àwọn Òkun,” 9/15
LÁJORÍ ÀPILẸ̀KỌ FÚN ÌKẸ́KỌ̀Ọ́
Aláyọ̀ Ni Àwọn Ìránṣẹ́ Jèhófà, 11/1
“Àṣẹ Àgbékalẹ̀ Jèhófà” Kò Lè Kùnà, 7/15
Àwámáridìí Ni Títóbi Jèhófà, 1/15
Àwọn Àgbàlagbà—Ẹni Ọ̀wọ́n Ni Wọ́n Nínú Ẹgbẹ́ Ará, 5/15
Àwọn Wo Ló Ń Fi Ògo fún Ọlọ́run Lónìí? 10/1
Bí A Ṣe Lè Máa Finú Rere Hàn Nínú Ayé Oníwà Òǹrorò Yìí, 4/15
Bí A Ṣe Lè Ní Èrò Kristi Nípa Ipò Ọlá, 8/1
Bíbójútó Àwọn Àgbàlagbà—Ojúṣe Àwọn Kristẹni, 5/15
‘Ẹ Kọ́ Wọn Láti Pa Gbogbo Ohun Tí Mo Ti Pa Láṣẹ fún Yín Mọ́,’ 7/1
“Ẹ Gbé Ẹ̀kúnrẹ́rẹ́ Ìhámọ́ra Ogun Láti Ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Wọ̀,” 9/15
Ẹ Jẹ́ Onígboyà Bíi Jeremáyà, 5/1
‘Ẹ Lọ, Kí Ẹ Sọ Àwọn Èèyàn Di Ọmọ Ẹ̀yìn’ 7/1
“Ẹ Máa Bá A Lọ Ní Gbígba Agbára Nínú Olúwa,” 9/15
Ẹ Máa “Fi Ẹnu Kan” Yin Ọlọ́run Lógo, 9/1
Ẹ Máa fún Ara Yín Lókun, 5/1
“Ẹ Ní Ìfẹ́ni Oníjẹ̀lẹ́ńkẹ́ fún Ara Yín,” 10/1
Ẹ Wá Jèhófà, Olùṣàyẹ̀wò Ọkàn, 11/15
‘Ẹrú Olóòótọ́’ Náà Yege Nígbà Àbẹ̀wò! 3/1
“Ẹrú” Tí Ó Jẹ́ Olóòótọ́ àti Olóye, 3/1
Ẹ Ṣọ́ra fún “Ohùn Àwọn Àjèjì,” 9/1
Ẹ̀yin Ọ̀dọ́, Ǹjẹ́ Ẹ Ń Múra Sílẹ̀ fún Ọjọ́ Ọ̀la? 5/1
Fi Ìgboyà Wàásù Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, 11/15
Fi Ojú Pàtàkì Wo Ẹ̀bùn Ìwàláàyè Rẹ, 6/15
Gbára Lé Ẹ̀mí Ọlọ́run Nígbà Tí Nǹkan Bá Yí Padà, 4/1
Ìbùkún Ni fún Àwọn Tó Ń Fi Ògo fún Ọlọ́run, 6/1
Ìdájọ́ Jèhófà Yóò Dé Sórí Àwọn Ẹni Ibi, 11/15
Inú-Rere-Onífẹ̀ẹ́ Jèhófà Pọ̀, 1/15
“Ìrísí Ìran Ayé Yìí Ń Yí Padà,” 2/1
“Ìró Wọn Jáde Lọ sí Gbogbo Ilẹ̀ Ayé,” 1/1
Ìṣẹ̀dá Ń Polongo Ògo Ọlọ́run! 6/1
Jèhófà Ni Olùrànlọ́wọ́ Wa, 12/15
Jèhófà Ń Pèsè Àwọn Ohun Tá A Nílò Lójoojúmọ́ (Àdúrà Olúwa), 2/1
Jèhófà Ń Ṣí Ògo Rẹ̀ Payá Fáwọn Onírẹ̀lẹ̀, 8/1
Jèhófà, ‘Odi Agbára Wa Ní Àkókò Wàhálà,’ 8/15
Jẹ́ Kí Ọlọ́run Alààyè Tọ́ Ẹ Sọ́nà, 6/15
Jẹ́ Oníwà Mímọ́ Nípa Dídáàbò Bo Ọkàn Rẹ, 2/15
Kí Gbogbo Ènìyàn Máa Kéde Ògo Jèhófà, 1/1
Kí Nìdí Tó O Fi Gbà Pé Párádísè Ń Bọ̀? 10/15
Kọ Ẹ̀mí Ayé Tó Ń Yí Padà Yìí, 4/1
“Lọ Káàkiri La Ilẹ̀ Náà Já,” 10/15
Máa Rìn Ní Ọ̀nà Ìwà Títọ́, 12/1
Ǹjẹ́ O Mọrírì Ìrànlọ́wọ́ Jèhófà? 12/15
Ǹjẹ́ O Ní Inú Dídùn sí “Òfin Jèhófà”? 7/15
“Olúwa, Kọ́ Wa Bí A Ṣe Ń Gbàdúrà” (Àdúrà Olúwa), 2/1
Ó Ń Rẹ̀ Wa àmọ́ A Kì Í Ṣàárẹ̀, 8/15
Ó Yẹ Kí Èèyàn Ọlọ́run Nífẹ̀ẹ́ Inú Rere, 4/15
“Ṣàṣeparí Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Rẹ Ní Kíkún,” 3/15
“Ṣe Iṣẹ́ Ajíhìnrere,” 3/15
Ṣọ́ra fún Ọtí Àmujù, 12/1
Ṣọ́ra fún Ẹ̀tàn, 2/15
Wọ́n Kórìíra Wa Láìnídìí, 8/15
Wọ́n Ń Ṣe Inúnibíni sí Wa Síbẹ̀ À Ń Láyọ̀, 11/1
Ọ̀KAN-Ò-JỌ̀KAN
Àdúrà Olúwa, 9/15
Àlàáfíà, 1/1
Àmì 666 Kì Í Ṣe Àdììtú Àmì, 4/1
Ánábatíìsì, 6/15
Aṣáájú Rere, 11/1
Àwọn Eré Ìdárayá Ayé Àtijọ́, 5/1
Àwọn Ìránṣẹ́ Ọlọ́run Dà Bí Igi, 3/1
Àwọn Nǹkan Tẹ̀mí, 10/15
‘Àwọn Ọlọ́kàn Tútù Ni Yóò Jogún Ayé,’ 10/1
Àwọn Ọlọ Tó Pilẹ̀ Oúnjẹ, 9/15
Éhúdù, 3/15
Ẹranko Ẹhànnà Náà àti Àmì Rẹ̀, 4/1
Ibi Tá A Ti Lè Rí Ìmọ̀ràn Tó Ṣeni Láǹfààní, 8/15
Ìjọba Rere, 8/1
Ìjọba Ọlọ́run Ń Gbé Nǹkan Ṣe Lónìí, 8/1
Ìjọsìn Tòótọ́ àti Ìbọ̀rìṣà Forí Gbárí (Éfésù), 12/15
Ìlérí Ta Lo Lè Gbẹ́kẹ̀ Lé? 1/15
Ìpàdé Àlàáfíà Westphalia, 3/15
Ipò Rẹ Nípa Tẹ̀mí àti Ìlera Rẹ, 2/1
Kapadókíà, 7/15
Kí Ló Ń Mú Kí Ayé Ẹni Dára? 8/1
Lẹ́tà Tí Ọmọbìnrin Kan Kọ sí Nóà, 7/1
Ǹjẹ́ Àdúrà Lè Yí Ìṣòro Rẹ Padà? 6/15
Ǹjẹ́ A Lè Yọ Ṣọ́ọ̀ṣì Nínú Ìṣòro? 3/1
Ǹjẹ́ Ó Yẹ Ká Máa Gbàdúrà sí Àwọn Áńgẹ́lì? 4/1
Ǹjẹ́ Ó Yẹ Kó O Ní Ẹ̀sìn Tìrẹ? 6/1
Ǹjẹ́ Ó Wù Ọ́ Láti Wà Láàyè Títí Láé? 11/15
Ǹjẹ́ Ó Yẹ Káwọn Àlùfáà Máa Lọ́wọ́ Nínú Ìṣèlú? 5/1
Ohun Tó Ń Fúnni Láyọ̀, 9/1
Ohun Tó O Nílò Nípa Tẹ̀mí, 2/1
“Ọ̀kan Lára Àwọn Àgbà Iṣẹ́,” 1/15
“Ọlọ́run Tòótọ́ Náà àti Ìyè Àìnípẹ̀kun” (1Jo 5:20), 10/15
Rèbékà, 4/15
Ṣé Ìsìn Ló Fa Ìṣòro Aráyé? 2/15
‘Wọ́n Ṣíkọ̀ Lọ sí Kípírọ́sì,’ 7/1