ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb16 September ojú ìwé 5
  • September 19 sí 25

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • September 19 sí 25
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
mwb16 September ojú ìwé 5

September 19 Sí 25

SÁÀMÙ 135-141

  • Orin 59 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Ọlọ́run Ṣẹ̀dá Wa Tìyanu-Tìyanu”: (10 min.)

    • Sm 139:14—Tá a bá ronú jinlẹ̀ nípa iṣẹ́ ọwọ́ Jèhófà, èyí á jẹ́ ká túbọ̀ mọrírì àwọn ohun tó ṣe (w07 6/15 ojú ìwé 21 ìpínrọ̀ 1 sí 4)

    • Sm 139:15, 16—Àwọn sẹ́ẹ̀lì àtàwọn èròjà tó ń pinnu bí ẹnì kọ̀ọ̀kan wa ṣe máa rí jẹ́ ká mọ bí ọgbọ́n àti agbára Jèhófà ṣe pọ̀ tó (w07 6/15 ojú ìwé 22 àti 23 ìpínrọ̀ 7 sí 11)

    • Sm 139:17, 18—Ọ̀nà tí Jèhófà gbà ṣẹ̀dá àwa èèyàn ṣàrà ọ̀tọ̀ gan-an; oríṣiríṣi èdè là ń sọ, bá a sì ṣe ń ronú yàtọ̀ síra (w07 6/15 ojú ìwé 23 ìpínrọ̀ 12 àti 13; w06 9/1 ojú ìwé 16 ìpínrọ̀ 8)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)

    • Sm 136:15—Òye wo ni ẹsẹ Ìwé Mímọ́ yìí jẹ́ ká ní nípa ìwé Ẹ́kísódù? (it-1 ojú ìwé 783 ìpínrọ̀ 5)

    • Sm 141:5—Kí ni Dáfídì Ọba mọ̀? (w15 4/15 ojú ìwé 31 ìpínrọ̀ 1)

    • Ẹ̀kọ́ wo ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ mi nípa Jèhófà?

    • Àwọn kókó wo látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí ni mo lè lò lóde ẹ̀rí?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Sm 139:1-24

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (2 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) wp16.5 ojú ìwé 16

  • Ìpadàbẹ̀wò: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) wp16.5 ojú ìwé 16—Pe ẹni náà wá sípàdé.

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì: (6 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) fg ẹ̀kọ́ 8 ìpínrọ̀ 8—Ran akẹ́kọ̀ọ́ lọ́wọ́ kó lè rí bó ṣe lè fi ohun tó kọ́ sílò.

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 57

  • “Àwọn Nǹkan Tó Yẹ Kó O Yẹra fún Tó O Bá Ń Darí Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì”: (15 min.) Lẹ́yìn tẹ́ ẹ bá ti jíròrò àpilẹ̀kọ náà, jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò alápá-méjì nípa ọ̀nà tí kò tọ́ àti ọ̀nà tó tọ́ láti kọ́ni, èyí tó dá lé ìwé Bíbélì Fi Kọ́ni ojú ìwé 29, ìpínrọ̀ 7, kẹ́ ẹ sì jíròrò ohun tẹ́ ẹ wò nínú fídíò náà. Kí àwọn akéde náà máa fojú bá a lọ nínú ìwé wọn. Sọ fún àwọn ará pé kí wọ́n máa yẹra fún àwọn nǹkan yìí nígbà tí wọ́n bá ń ṣe iṣẹ́ akẹ́kọ̀ọ́, èyí ò ní jẹ́ kí wọ́n lò tó àkókò tá a yàn fún iṣẹ́ náà.

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) kr Lẹ́tà Látọ̀dọ̀ Ìgbìmọ̀ Olùdarí àti orí 1 ìpínrọ̀ 1 sí 10

  • Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)

  • Orin 30 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́