ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 September ojú ìwé 4
  • September 11-17

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • September 11-17
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 September ojú ìwé 4

September 11-17

ÌSÍKÍẸ́LÌ 46-48

  • Orin 134 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Ohun Tí Àwọn Ọmọ Ísírẹ́lì Máa Gbádùn Tí Wọ́n Bá Kúrò Nígbèkùn”: (10 min.)

    • Isk 47:1, 7-12​—Ilẹ̀ wọn máa di ilẹ̀ ọlọ́ràá (w99 3/1 10 ¶11-12)

    • Isk 47:13, 14​—Ìdílé kọ̀ọ̀kan ló máa gba ogún (w99 3/1 10 ¶10)

    • Isk 48:9, 10​—Kí wọ́n tó bẹ̀rẹ̀ sí í pín ilẹ̀ fún àwọn èèyàn, wọ́n á kọ́kọ́ ya apá ibi tó dára gan-an sọ́tọ̀ gẹ́gẹ́ bí “ọrẹ” fún Jèhófà

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)

    • Isk 47:1, 8; 48:30, 32-34​—Kí nìdí tí àwọn Júù tí wọ́n kó nígbèkùn yẹn kò fi retí pé kí gbogbo nǹkan tí Ìsíkíẹ́lì rí nínú ìràn tẹ́ńpìlì yẹn rí bẹ́ẹ̀ gẹ́lẹ́? (w99 3/1 11 ¶14)

    • Isk 47:6​—Kí ni ìdí tí ẹsẹ Ìwé Mímọ́ yìí fi pe Ìsíkíẹ́lì ní “ọmọ ènìyàn”? (it-2 1001)

    • Kí ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ ẹ nípa Jèhófà?

    • Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Isk 48:13-22

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (2 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Kókó iwájú ìwé ìròyìn wp17.5​—Jẹ́ kí onílé mọ̀ pé o máa pa dà wá.

  • Ìpadàbẹ̀wò: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) wp17.5​—Nígbà tó o kọ́kọ́ wàásù fún ẹni náà, o ti fún un ní ìwé ìròyìn yìí. Ṣe ìpadàbẹ̀wò, kó o sì fi ọ̀kan lára àwọn ìtẹ̀jáde tá a fi ń kọ́ àwọn èèyàn lẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì hàn án.

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì: (6 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) bh 34 ¶17​—Pe ẹni náà wá sí ìpàdé.

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Song 28

  • Ohun Tó Ń Fẹ́ Àbójútó Nínú Ìjọ: (8 min.) Tàbí kẹ́ ẹ jíròrò ohun tẹ́ ẹ rí kọ́ nínú Ìwé Ọdọọdún. (yb17 64-65)

  • Ohun Tí Ètò Ọlọ́run Ti Ṣe: (7 min.) Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò Ohun Tí Ètò Ọlọ́run Ti Ṣe ti oṣù September.

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) kr orí 17 ¶19-20, àpótí “Àwọn Ilé Ẹ̀kọ́ Tó Ń Dá Àwọn Òjíṣẹ́ Ìjọba Ọlọ́run Lẹ́kọ̀ọ́,” àpótí tó wà fún àtúnyẹ̀wò “Ṣé O Gbà Lóòótọ́ Pé Ìjọba Ọlọ́run Ti Ń Ṣàkóso?”

  • Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)

  • Orin 11 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́