ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 September ojú ìwé 4
  • Ohun Tí Àwọn Ọmọ Ísírẹ́lì Máa Gbádùn Tí Wọ́n Bá Kúrò Nígbèkùn

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tí Àwọn Ọmọ Ísírẹ́lì Máa Gbádùn Tí Wọ́n Bá Kúrò Nígbèkùn
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • “Fi Ọkàn-àyà Rẹ Sí” Tẹ́ńpìlì Ọlọ́run!
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1999
  • “Pín Ilẹ̀ Náà Bí Ogún”
    Ìjọsìn Mímọ́ Jèhófà Ti Pa Dà Bọ̀ Sípò!
  • “Òfin Tẹ́ńpìlì Náà Nìyí”
    Ìjọsìn Mímọ́ Jèhófà Ti Pa Dà Bọ̀ Sípò!
  • “Ṣàlàyé Bí Tẹ́ńpìlì Náà Ṣe Rí”
    Ìjọsìn Mímọ́ Jèhófà Ti Pa Dà Bọ̀ Sípò!
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 September ojú ìwé 4

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | ÌSÍKÍẸ́LÌ 46-48

Ohun Tí Àwọn Ọmọ Ísírẹ́lì Máa Gbádùn Tí Wọ́n Bá Kúrò Nígbèkùn

Ìran tẹ́ńpìlì tí Ìsíkíẹ́lì rí fún àwọn ọmọ Ísírẹ́lì tó wà nígbèkùn ní ìṣírí, ó sì tún fi dá wọn lójú pé wọ́n ṣì máa kúrò nígbèkùn gẹ́gẹ́ bí àsọtẹ́lẹ̀ ṣe sọ. Ìjọsìn mímọ́ ni gbogbo àwọn tí Jèhófà ti bù kún á máa ṣe.

Àwọn ọmọ Ísírẹ́lì tó pa dà láti ìgbèkùn ń gbádùn ilẹ̀ ọlọ́ràá náà

Ìran yẹn fi hàn pé nǹkan máa wà létòlétò, àwọn èèyàn á fọwọ́ sowọ́ pọ̀, Jèhófà sì máa dáàbò bò wọ́n

47:7-14

  • Ilẹ̀ ọlọ́ràá tó ń mú èso jáde

  • Ìdílé kọ̀ọ̀kan ló máa gba ogún

Kí wọ́n tó bẹ̀rẹ̀ sí í pín ilẹ̀ fún àwọn èèyàn, wọ́n á kọ́kọ́ ya apá ibi tó dára gan-an sọ́tọ̀ gẹ́gẹ́ bí “ọrẹ” fún Jèhófà

48:9, 10

Báwo ni mo ṣe lè fi hàn pé ìjọsìn Jèhófà ni mo kà sí pàtàkì jù nígbèésí ayé mi? (w06 4/15 27-28 ¶13-14)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́