ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 September ojú ìwé 5
  • September 18-24

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • September 18-24
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 September ojú ìwé 5

September 18-24

DÁNÍẸ́LÌ 1-3

  • Orin 131 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Jèhófà Máa San Wá Lẹ́san Tá A Bá Jẹ́ Adúróṣinṣin sí I”: (10 min.)

    • [Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Dáníẹ́lì.]

    • Da 3:16-20​—Àwọn ọ̀rẹ́ Dáníẹ́lì jẹ́ adúróṣinṣin sí Jèhófà nígbà tí wọ́n kojú àdánwò ńlá (w15 7/15 25 ¶15-16)

    • Da 3:26-29​—Ìdúróṣinṣin wọn fi ìyìn fún Jèhófà, Jèhófà sì san wọ́n lẹ́san (w13 1/15 10 ¶13)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (8 min.)

    • Da 1:5, 8​—Kí nìdí tí Dáníẹ́lì àtàwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ mẹ́tẹ̀ẹ̀ta fi gbà pé táwọn bá jẹ oúnjẹ tí ọba gbé kalẹ̀, ó máa sọ àwọn di ẹlẹ́gbin? (it-2 382)

    • Da 2:44​—Kí nìdí tí Ìjọba Ọlọ́run fi máa fòpin sí àwọn ìjọba ayé tí ère yẹn ṣàpẹẹrẹ? (w12 6/15 17, àpótí; w01 10/15 6 ¶4)

    • Kí ni Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí kọ́ ẹ nípa Jèhófà?

    • Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí látinú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Da 2:31-43

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (2 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ais 40:22​—Máa Fi Òtítọ́ Kọ́ni​—Jẹ́ kí onílé mọ̀ pé o máa pa dà wá.

  • Ìpadàbẹ̀wò: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ro 15:4​—Máa Fi Òtítọ́ Kọ́ni​—Fún un ní káàdì ìkànnì JW.ORG.

  • Àsọyé: (6 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) w17.02 29-30​—Àkòrí: Ṣé Jèhófà Ti Kọ́kọ́ Máa Ń Díwọ̀n Ohun Tá A Lè Mú Mọ́ra Kó Tó Wá Pinnu Irú Àdánwò Tó Máa Jẹ́ Kó Dé Bá Wa?

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 63

  • “Jẹ́ Adúróṣinṣin Nígbà Ìdẹwò”: (8 min.) Ìjíròrò.

  • “Jẹ́ Adúróṣinṣin Nígbà Tí Wọ́n Bá Yọ Mọ̀lẹ́bí Rẹ Kan Lẹ́gbẹ́”: (7 min.) Ìjíròrò.

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) kr “Apá 6​—Ṣíṣètìlẹyìn Fún Iṣẹ́ Ìjọba Ọlọ́run—​À Ń Kọ́ Ibi Ìjọsìn, A sì Ń Ṣèrànwọ́ Nígbà Àjálù,” orí 18 ¶1-8

  • Àtúnyẹ̀wò àti Ohun Tá A Máa Kọ́ Lọ́sẹ̀ Tó Ń Bọ̀ (3 min.)

  • Orin 101 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́