ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb20 June ojú ìwé 6
  • June 22-28

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • June 22-28
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
mwb20 June ojú ìwé 6

June 22-28

Ẹ́KÍSÓDÙ 1-3

  • Orin 7 àti Àdúrà

  • Ọ̀rọ̀ Ìbẹ̀rẹ̀ (1 min.)

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

  • “Èmi Yóò Di Ohun Tí Mo Bá Fẹ́”: (10 min.)

    • [Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Ẹ́kísódù.]

    • Ẹk 3:13​—Mósè fẹ́ mọ ohun tí orúkọ Jèhófà túmọ̀ sí àti irú ẹni tó jẹ́ (w13 3/15 25 ¶4)

    • Ẹk 3:14​—Jèhófà lè di ohunkóhun tó bá fẹ́ láti mú ohun tó ní lọ́kàn ṣẹ (kr 43, àpótí)

  • Máa Walẹ̀ Jìn Nínú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run: (10 min.)

    • Ẹk 2:10​—Kí nìdí tó fi bọ́gbọ́n mu láti gbà pé ọmọbìnrin Fáráò gba Mósè ṣọmọ? (g04 4/8 6 ¶5)

    • Ẹk 3:1​—Irú àlùfáà wo ni Jẹ́tírò? (w04 3/15 24 ¶4)

    • Àwọn ìṣúra tẹ̀mí wo lo tún rí nínú Bíbélì kíkà ọ̀sẹ̀ yìí nípa Jèhófà, iṣẹ́ ìwàásù tàbí àwọn nǹkan míì?

  • Bíbélì Kíkà: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Ẹk 2:11-25 (th ẹ̀kọ́ 11)

MÁA LO ARA RẸ LẸ́NU IṢẸ́ ÌWÀÁSÙ

  • Nígbà Àkọ́kọ́: (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ. Onílé sọ ohun táwọn èèyàn sábà máa ń sọ ní ìpínlẹ̀ yín tí wọn kò bá fẹ́ gbọ́ ìwàásù. Fèsì ní ṣókí, kó o sì máa bá ọ̀rọ̀ rẹ lọ. (th ẹ̀kọ́ 16)

  • Ìpadàbẹ̀wò: (4 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) Lo ohun tá a lè bá àwọn èèyàn sọ. Lẹ́yìn náà, fún onílé ní ìwé ìròyìn lọ́ọ́lọ́ọ́ kan tó jíròrò ohun tí onílé náà sọ̀rọ̀ nípa ẹ̀. (th ẹ̀kọ́ 12)

  • Àsọyé: (5 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀) w02 6/15 11 ¶1-4​—Àkòrí: Ohun Kan Tó Níye Lórí Ju Àwọn Ìṣúra Íjíbítì Lọ. (th ẹ̀kọ́ 13)

MÁA HÙWÀ TÓ YẸ KRISTẸNI

  • Orin 2

  • Di Ọ̀rẹ́ Jèhófà​—Orúkọ Jèhófà: (6 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò náà. Lẹ́yìn náà, tó bá ṣeé ṣe, pe àwọn ọmọdé bíi mélòó kan wá sórí pèpéle, kó o sì bi wọ́n pé: Kí ni orúkọ Jèhófà túmọ̀ sí? Kí láwọn nǹkan tí Jèhófà dá? Ọ̀nà wo ni Jèhófà lè gbà ràn ẹ́ lọ́wọ́?

  • Ọlọ́run Gbé Orúkọ Rẹ̀ Ga ní Scandinavia: (9 min.) Ìjíròrò. Jẹ́ kí àwọn ará wo fídíò náà. Lẹ́yìn náà, béèrè àwọn ìbéèrè yìí: Kí nìdí tí ọ̀pọ̀ èèyàn ò fi mọ orúkọ Ọlọ́run ṣáájú àwọn ọdún 1500? Báwo ni wọ́n ṣe bẹ̀rẹ̀ sí í lo orúkọ Jèhófà ní Scandinavia? Kí nìdí tó o fi mọyì Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun?

  • Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ìjọ: (30 min.) jy orí 120

  • Ọ̀rọ̀ Ìparí (3 min. tàbí kó máà tó bẹ́ẹ̀)

  • Orin 104 àti Àdúrà

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́