ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • wp21 No. 1 ojú ìwé 16
  • Ṣé Ọlọ́run Ń Gbọ́ Àdúrà Rẹ?

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ṣé Ọlọ́run Ń Gbọ́ Àdúrà Rẹ?
  • Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tá À Ń Fi Sóde)—2021
  • Ìsọ̀rí
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • KÍ NI BÍBÉLÌ SỌ?
  • Ṣé Ọlọ́run Ń Gbọ́ Àdúrà Wa?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tá À Ń Fi Sóde)—2021
  • Ìdí Tí Ọlọ́run Fi Fẹ́ Ká Máa Gbàdúrà sí Òun
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2015
  • Ẹ Sọ Ẹ̀dùn Ọkàn Yín Fún Ọlọ́run
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2006
  • Àǹfààní Pàtàkì Ni Àdúrà Jẹ́
    Kí Ni Bíbélì Kọ́ Wa?
Àwọn Míì
Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tá À Ń Fi Sóde)—2021
wp21 No. 1 ojú ìwé 16

Ṣé Ọlọ́run ń gbọ́ Àdúrà Rẹ?

Tó o bá ń gbàdúrà, ṣé o rò pé Ọlọ́run ń tẹ́tí sí ẹ lóòótọ́?

KÍ NI BÍBÉLÌ SỌ?

Obìnrin kan ń ka Bíbélì.
  • Ọlọ́run ń fetí sílẹ̀. Bíbélì fi dá wa lójú pé: “Jèhófà wà nítòsí gbogbo àwọn tó ń ké pè é, nítòsí gbogbo àwọn tó ń ké pè é ní òtítọ́. . . . Ó ń gbọ́ igbe wọn fún ìrànlọ́wọ́.”​—Sáàmù 145:18, 19.

  • Ọlọ́run fẹ́ kó o máa gbàdúrà sí òun. Bíbélì rọ̀ wá pé: “Nínú ohun gbogbo nípasẹ̀ àdúrà àti ìrawọ́ ẹ̀bẹ̀ pẹ̀lú ìdúpẹ́, ẹ máa sọ àwọn ohun tí ẹ̀ ń tọrọ fún Ọlọ́run.”​—Fílípì 4:6.

  • Ọlọ́run ń bójú tó ẹ lóòótọ́. Ọlọ́run mọ àwọn ìṣòro àti àníyàn rẹ, ó sì fẹ́ ràn ẹ́ lọ́wọ́. Bíbélì sọ pé: “Ẹ máa kó gbogbo àníyàn yín lọ sọ́dọ̀ rẹ̀, torí ó ń bójú tó yín.”​—1 Pétérù 5:7.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́