ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • yb16 ojú ìwé 8-ojú ìwé 9 ìpínrọ̀ 1
  • Àwọn Ohun Pàtàkì Tó Ṣẹlẹ̀ Lọ́dún Tó Kọjá

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ohun Pàtàkì Tó Ṣẹlẹ̀ Lọ́dún Tó Kọjá
  • Ìwé Ọdọọdún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà—2016
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ṣé Wàá Jẹ́ Onítara Bíi Ti Jèhófà àti Jésù Nígbà Ìrántí Ikú Kristi Tó Ń Bọ̀ Yìí?
    Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Ìjọba Wa—2015
  • Jẹ́ Kí “Iná Ẹ̀mí Máa Jó Nínú” Rẹ
    Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Ìjọba Wa—2009
  • Ẹ Má Ṣe Jẹ́ Kí Iná Ìtara Yín fún Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Jó Rẹ̀yìn
    Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Ìjọba Wa—2007
  • Ẹ Jẹ́ Onítara Fún Ìjọsìn Tòótọ́
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2010
Àwọn Míì
Ìwé Ọdọọdún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà—2016
yb16 ojú ìwé 8-ojú ìwé 9 ìpínrọ̀ 1
Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà ń kọ́ ọ́fíìsì àwọn atúmọ̀ èdè Aymara ní ìlú El Alto ní orílẹ̀-èdè Bòlífíà

Bòlífíà: Wọ́n ń kọ́ ọ́fíìsì àwọn atúmọ̀ èdè Aymara ní ìlú El Alto

Àwọn ohun pàtàkì tó ṣẹlẹ̀ lọ́dún tó kọjá

NÍGBÀ tí Bíbélì ń ṣàlàyé ohun tí Ọlọ́run máa gbé ṣe nípasẹ̀ Ìjọba rẹ̀, Áísáyà 9:7 sọ pé: “Ìtara Jèhófà àwọn ẹgbẹ́ ọmọ ogun yóò ṣe èyí.” Bẹ́ẹ̀ náà ni Jésù tó jẹ́ Ọba Ìjọba yẹn ṣe fi ìtara tó lé kenkà hàn fún ìjọsìn tòótọ́ jálẹ̀ iṣẹ́ òjíṣẹ́ rẹ̀ lórí ilẹ̀ ayé. (Jòh. 2:17) Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà kárí ayé náà ń tẹ̀ lé àpẹẹrẹ Jèhófà àti Jésù bá a ṣe ń fi ìtara wàásù káwọn èèyàn lè wá jadùn ìfẹ́ Jèhófá, Bàbá wa ọ̀run. Àwọn ìròyìn tó tẹ̀ lé e yìí fi hàn pé òótọ́ lọ̀rọ̀ yìí.

Àwọn tó péjọ ń fetí sílẹ̀ sí ìtòlẹ́sẹẹsẹ àpéjọ agbègbè àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà tá a ṣe ní orílẹ̀-èdè El Salvador

El salvador: Àpéjọ agbègbè 2015

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́