Ẹ́KÍSÓDÙ
OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ
1
Àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ń pọ̀ sí i ní Íjíbítì (1-7)
Fáráò ń fìyà jẹ àwọn ọmọ Ísírẹ́lì (8-14)
Àwọn agbẹ̀bí tó bẹ̀rù Ọlọ́run dá ẹ̀mí sí (15-22)
2
Wọ́n bí Mósè (1-4)
Ọmọbìnrin Fáráò fi Mósè ṣe ọmọ rẹ̀ (5-10)
Mósè sá lọ sí Mídíánì, ó sì fẹ́ Sípórà (11-22)
Ọlọ́run gbọ́ bí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ṣe ń kérora (23-25)
3
Mósè àti igi ẹlẹ́gùn-ún tó ń jó (1-12)
Jèhófà sọ ìtúmọ̀ orúkọ Rẹ̀ (13-15)
Jèhófà fún Mósè ní ìtọ́ni (16-22)
4
Iṣẹ́ àmì mẹ́ta tí Mósè máa ṣe (1-9)
Mósè ní òun ò kúnjú ìwọ̀n (10-17)
Mósè pa dà sí Íjíbítì (18-26)
Mósè àti Áárónì tún jọ pàdé (27-31)
5
Mósè àti Áárónì lọ bá Fáráò (1-5)
Wọ́n túbọ̀ fìyà jẹ àwọn ọmọ Ísírẹ́lì (6-18)
Àwọn ọmọ Ísírẹ́lì dá Mósè àti Áárónì lẹ́bi (19-23)
6
Ọlọ́run tún ṣèlérí òmìnira ((1-13)
Ìlà ìdílé Mósè àti Áárónì (14-27)
Mósè tún máa lọ sọ́dọ̀ Fáráò (28-30)
7
Jèhófà fún Mósè lókun (1-7)
Ọ̀pá Áárónì di ejò ńlá (8-13)
Ìyọnu 1: omi di ẹ̀jẹ̀ (14-25)
8
9
Ìyọnu 5: àwọn ẹran ọ̀sìn kú (1-7)
Ìyọnu 6: eéwo yọ sára èèyàn àti ẹranko (8-12)
Ìyọnu 7: òjò yìnyín (13-35)
10
Ìyọnu 8: eéṣú (1-20)
Ìyọnu 9: òkùnkùn (21-29)
11
12
Ó fi Ìrékọjá lọ́lẹ̀ (1-28)
Ìyọnu 10: Ó pa àkọ́bí (29-32)
Wọ́n bẹ̀rẹ̀ sí í kúrò ní ilẹ̀ náà (33-42)
Ìtọ́ni fún àwọn tó fẹ́ ṣe Ìrékọjá (43-51)
13
Ti Jèhófà ni gbogbo àkọ́bí tó jẹ́ akọ (1, 2)
Àjọyọ̀ Búrẹ́dì Aláìwú (3-10)
Kí wọ́n ya gbogbo àkọ́bí tó jẹ́ akọ sọ́tọ̀ fún Ọlọ́run (11-16)
Ọlọ́run darí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì gba ọ̀nà Òkun Pupa (17-20)
Ọwọ̀n ìkùukùu àti ọwọ̀n iná (21, 22)
14
Ísírẹ́lì dé òkun (1-4)
Fáráò ń lépa àwọn ọmọ Ísírẹ́lì (5-14)
Àwọn ọmọ Ísírẹ́lì sọdá Òkun Pupa (15-25)
Àwọn ará Íjíbítì rì sínú òkun (26-28)
Àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ní ìgbàgbọ́ nínú Jèhófà (29-31)
15
Mósè àti àwọn ọmọ Ísírẹ́lì kọrin ìṣẹ́gun (1-19)
Míríámù fi orin dáhùn pa dà (20, 21)
Omi tó korò wá dùn (22-27)
16
Àwọn èèyàn ń ráhùn torí oúnjẹ (1-3)
Jèhófà gbọ́ ìráhùn wọn (4-12)
Ó fún wọn ní ẹyẹ àparò àti mánà (13-21)
Kò sí mánà lọ́jọ́ Sábáàtì (22-30)
Wọ́n tọ́jú mánà fún ìrántí (31-36)
17
Wọ́n ráhùn pé wọn ò rí omi mu ní Hórébù (1-4)
Omi jáde látinú àpáta (5-7)
Àwọn ọmọ Ámálékì gbógun ja Ísírẹ́lì, àmọ́ wọn ò borí (8-16)
18
19
Ní Òkè Sínáì (1-25)
Ísírẹ́lì yóò di ìjọba àwọn àlùfáà (5, 6)
Ó sọ àwọn èèyàn di mímọ́ láti pàdé Ọlọ́run (14, 15)
20
21
22
23
Ìdájọ́ tí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì máa tẹ̀ lé (1-19)
Áńgẹ́lì yóò máa darí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì (20-26)
Gbígba ilẹ̀ àti ààlà (27-33)
24
25
26
27
28
Àwọn aṣọ àlùfáà (1-5)
Éfódì (6-14)
Aṣọ ìgbàyà (15-30)
Aṣọ àwọ̀lékè tí kò lápá (31-35)
Láwàní àti àwo dídán (36-39)
Àwọn aṣọ míì tó jẹ́ ti àwọn àlùfáà (40-43)
29
30
Pẹpẹ tùràrí (1-10)
Ìkànìyàn àti owó ètùtù (11-16)
Bàsíà bàbà láti máa fi wẹ̀ (17-21)
Àkànṣe òróró àfiyanni (22-33)
Àwọn èròjà tùràrí mímọ́ (34-38)
31
32
33
Ọlọ́run bá àwọn ọmọ Ísírẹ́lì wí (1-6)
Àgọ́ ìpàdé ní ẹ̀yìn ibùdó (7-11)
Mósè fẹ́ rí ògo Jèhófà (12-23)
34
Ó gbẹ́ àwọn wàláà òkúta míì (1-4)
Mósè rí ògo Jèhófà (5-9)
Ọlọ́run tún àwọn ọ̀rọ̀ májẹ̀mú náà sọ (10-28)
Ìtànṣán ń jáde lára awọ ojú Mósè (29-35)
35
36
37
38
39
Wọ́n ṣe àwọn aṣọ àlùfáà (1)
Éfódì (2-7)
Aṣọ ìgbàyà (8-21)
Aṣọ àwọ̀lékè tí kò lápá (22-26)
Àwọn aṣọ míì tó jẹ́ ti àwọn àlùfáà (27-29)
Àwo wúrà (30, 31)
Mósè yẹ iṣẹ́ tí wọ́n ṣe sí àgọ́ ìjọsìn wò (32-43)
40