ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • nwt ojú ìwé 678
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Ẹ́sítà

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Ẹ́sítà
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Módékáì Àti Ẹ́sítérì
    Ìwé Ìtàn Bíbélì
  • Ó Lo Ọgbọ́n àti Ìgboyà, Ó sì Yọ̀ǹda Ara Rẹ̀ Tinútinú
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2012
  • Àwọn Kókó Pàtàkì Látinú Ìwé Ẹ́sítérì
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2006
  • Ẹ́sítà Gba Àwọn Èèyàn Ẹ̀ Nínú Ewu
    Àwọn Ẹ̀kọ́ Tó O Lè Kọ́ Látinú Bíbélì
Àwọn Míì
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Ẹ́sítà

Ẹ́SÍTÀ

OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ

  • 1

    • Ọba Ahasuérúsì se àsè ńlá ní Ṣúṣánì (1-9)

    • Fáṣítì Ayaba kò ṣègbọràn (10-12)

    • Ọba fọ̀rọ̀ lọ àwọn amòye rẹ̀ (13-20)

    • Wọ́n fi àṣẹ ọba ránṣẹ́ (21, 22)

  • 2

    • Wọ́n wá ayaba tuntun (1-14)

    • Ẹ́sítà di ayaba (15-20)

    • Módékáì tú àṣírí àwọn ọlọ̀tẹ̀ (21-23)

  • 3

    • Ọba gbé Hámánì ga (1-4)

    • Hámánì gbèrò láti pa àwọn Júù run (5-15)

  • 4

    • Módékáì ṣọ̀fọ̀ (1-5)

    • Módékáì ní kí Ẹ́sítà bá àwọn bẹ ọba (6-17)

  • 5

    • Ẹ́sítà wá síwájú ọba (1-8)

    • Hámánì ń bínú, ó sì ń gbéra ga (9-14)

  • 6

    • Ọba dá Módékáì lọ́lá (1-14)

  • 7

    • Ẹ́sítà tú Hámánì fó (1-6a)

    • Wọ́n gbé Hámánì kọ́ sórí òpó igi tó ṣe (6b-10)

  • 8

    • Ọba gbé Módékáì ga (1, 2)

    • Ẹ́sítà bẹ ọba (3-6)

    • Àṣẹ tí ọba fi ta ko àṣẹ àkọ́kọ́ (7-14)

    • Àwọn Júù rí ìtura, wọ́n sì ń yọ̀ (15-17)

  • 9

    • Àwọn Júù ṣẹ́gun (1-19)

    • Wọ́n dá àjọyọ̀ Púrímù sílẹ̀ (20-32)

  • 10

    • Módékáì di ẹni ńlá (1-3)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́