ÉFÉSÙ
OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ
1
Ìkíni (1, 2)
Àwọn ìbùkún tẹ̀mí (3-7)
À ń kó ohun gbogbo jọ nínú Kristi (8-14)
“Iṣẹ́ àbójútó kan” ní àwọn àkókò tí a ti yàn (10)
A fi ẹ̀mí gbé èdìdì lé wọn gẹ́gẹ́ bí “àmì ìdánilójú” (13, 14)
Pọ́ọ̀lù dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run nítorí ìgbàgbọ́ àwọn ará Éfésù, ó sì gbàdúrà fún wọn (15-23)
2
3
4
5
Ọ̀rọ̀ mímọ́ àti ìwà mímọ́ (1-5)
Ẹ máa rìn gẹ́gẹ́ bí ọmọ ìmọ́lẹ̀ (6-14)
Ẹ máa kún fún ẹ̀mí (15-20)
Ìmọ̀ràn fún àwọn ọkọ àti ìyàwó (21-33)
6
Ìmọ̀ràn fún àwọn ọmọ àti òbí (1-4)
Ìmọ̀ràn fún àwọn ẹrú àti ọ̀gá (5-9)
Gbogbo ìhámọ́ra ogun láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run (10-20)
Ìkíni tó fi parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ (21-24)