ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • nwt ojú ìwé 1565
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Fílípì

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Fílípì
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé 2 Jòhánù
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • Ẹpafíródítù—Òjíṣẹ́ Aṣojú Àwọn Ará Fílípì
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1996
  • Eeṣe Ti A Fi Nilati Gbé Irẹlẹ Wọ̀?
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1991
  • Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Éfésù
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Àwọn Míì
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Fílípì

FÍLÍPÌ

OHUN TÓ WÀ NÍNÚ ÌWÉ YÌÍ

  • 1

    • Ìkíni (1, 2)

    • Ọpẹ́ ni fún Ọlọ́run; Àdúrà Pọ́ọ̀lù (3-11)

    • Ìhìn rere ń tẹ̀ síwájú kódà lójú wàhálà (12-20)

    • Ààyè mi jẹ́ ti Kristi, ikú mi jẹ́ èrè (21-26)

    • Ẹ máa hùwà lọ́nà tó yẹ ìhìn rere (27-30)

  • 2

    • Ìrẹ̀lẹ̀ Kristẹni (1-4)

    • Ìrẹ̀lẹ̀ Kristi àti ìgbéga rẹ̀ (5-11)

    • Ẹ máa ṣiṣẹ́ ìgbàlà yín yọrí (12-18)

      • Ẹ máa tàn bí ìmọ́lẹ̀ (15)

    • Ó rán Tímótì àti Ẹpafíródítù (19-30)

  • 3

    • Ẹ má ṣe gbẹ́kẹ̀ lé ẹran ara (1-11)

      • Ohun gbogbo jẹ́ àdánù nítorí Kristi (7-9)

    • Mò ń nàgà láti gba èrè náà (12-21)

      • Ìlú ìbílẹ̀ wa wà ní ọ̀run (20)

  • 4

    • Ìṣọ̀kan, ayọ̀, èrò tí ó tọ́ (1-9)

      • Ẹ má ṣe máa ṣàníyàn nípa ohunkóhun (6, 7)

    • Pọ́ọ̀lù mọyì ẹ̀bùn àwọn ará Fílípì (10-20)

    • Ìkíni tó fi parí ọ̀rọ̀ rẹ̀ (21-23)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́