ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • km 7/13 ojú ìwé 8
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
  • Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Ìjọba Wa—2013
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Ìjọba Wa—2011
  • Báwo Ni Mo Ṣe Lè Yẹra Fún Wíwo Àwòrán Oníhòòhò?
    Jí!—2008
  • Kí Nìdí Tí Kò Fi Yẹ Kí N Máa Wo Àwòrán Oníhòòhò?
    Àwọn Ìbéèrè Tí Àwọn Ọ̀dọ́ Ń Béèrè—Àwọn Ìdáhùn Tí Ó Gbéṣẹ́, Apá Kejì
  • Àwòrán Oníhòòhò​—Ó Léwu Àbí Kò Léwu?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2013
Àwọn Míì
Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Ìjọba Wa—2013
km 7/13 ojú ìwé 8

Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò

Láti Bẹ̀rẹ̀ Ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì Ní Sátidé Àkọ́kọ́ Lóṣù August

“Ó fẹ́rẹ̀ẹ́ jẹ́ gbogbo èèyàn ló máa ń gbàdúrà. Kódà àwọn tí kò gba Ọlọ́run gbọ́ máa ń gbàdúrà tí wọ́n bá níṣòro. Ǹjẹ́ o rò pé gbogbo àdúrà ni Ọlọ́run ń gbọ́?” Jẹ́ kó fèsì. Fi ẹ̀yìn Ilé Ìṣọ́ August 1 hàn án, kẹ́ ẹ sì jọ jíròrò àlàyé tó dá lórí ìbéèrè àkọ́kọ́ àti ó kéré tán ọ̀kan lára àwọn ẹsẹ Bíbélì tó wà níbẹ̀. Fún un ní ìwé ìròyìn náà, kẹ́ ẹ sì jọ ṣàdéhùn ìgbà tí wàá pa dà lọ jíròrò ìbéèrè tó kàn.

Àkíyèsí: Kí ẹ ṣe àṣefihàn ọ̀nà ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ yìí ní ìpàdé fún iṣẹ́ ìsìn pápá tẹ́ ẹ máa ṣe ní August 3.

Ilé Ìṣọ́ August 1

“À ń bá àwọn èèyàn sọ̀rọ̀ nípa bí àwọn ohun tó ń mú ọkàn fà sí ìṣekúṣe ṣe gbòde kan lónìí. Àmọ́ ọ̀pọ̀ èèyàn ló rò pé kò sí ohun tó burú nínú bó ṣe wà káàkiri. Kí lèrò tìẹ? [Jẹ́ kó fèsì.] Jésù sọ pé èso tí igi kan so la fi ń mọ irú igi tó jẹ́. [Ka Mátíù 7:17.] Ìwé ìròyìn yìí ṣàlàyé àwọn ìṣòro tí àwọn ohun tó ń mú ọkàn fà sí ìṣekúṣe máa ń fà. Ó sì tún jẹ́ ká mọ ohun téèyàn lè ṣe láti jáwọ́ nínú rẹ̀.”

Jí! July–August

“Ẹ jẹ́ mọ̀ pé bí ẹni tó ń ṣàkóso ayé yìí ṣe burú náà ni ìwà àwọn èèyàn ṣe burú tó. Àmọ́, ṣé o mọ ẹni tó ń ṣàkóso ayé yìí? [Jẹ́ kó fèsì.] Gbọ́ ohun tí Ọlọ́run máa ṣe láti fòpin sí ìṣàkóso Sátánì. [Ka Jòhánù 12:31.] Ìwé ìròyìn yìí tú àṣírí irú ẹni tí Sátánì jẹ́ gan-an. Ó sì tún sọ àwọn ohun tá a lè ṣe láti dáàbò bo ara wa lọ́wọ́ àwọn ètekéte rẹ̀.” Fi àpilẹ̀kọ tó bẹ̀rẹ̀ lójú ìwé 14 hàn án.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́