ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb16 January ojú ìwé 1
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Ìsọ̀rí
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • ILÉ ÌṢỌ́
  • ILÉ ÌṢỌ́ (ẹ̀yìn ìwé)
  • ÌRÒYÌN AYỌ̀ LÁTỌ̀DỌ̀ ỌLỌ́RUN!
  • KỌ Ọ̀NÀ ÌGBỌ́RỌ̀KALẸ̀ RẸ
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
mwb16 January ojú ìwé 1
Àwọn arábìnrin kan ń fi ìwé Ìròyìn Ayọ̀ lọni ní orílẹ̀-èdè Madagascar

Àwọn arábìnrin kan ń fi ìwé Ìròyìn Ayọ̀ lọni ní orílẹ̀-èdè Madagascar

Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò

ILÉ ÌṢỌ́

Àwòrán iwájú ìwé ìròyìn Ilé Ìṣọ́ January 2016 | Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Ká Jẹ́ Olóòótọ́?

Béèrè ìbéèrè: Ǹjẹ́ o rò pé ayé yìí máa dùn-ún gbé tí gbogbo èèyàn bá ń tẹ̀ lé ìlànà yìí?

Ka Bíbélì: Heb 13:18

Fi ìwé lọni: Bíbélì gbà wá níyànjú pé ká jẹ́ olóòótọ́ nínú ohun gbogbo. Torí náà, ó yẹ ká máa ṣòótọ́ ní gbogbo apá ìgbésí ayé wa. Ìwé ìròyìn Ilé Ìṣọ́ yìí sọ̀rọ̀ nípa ìdí tó fi yẹ ká jẹ́ olóòótọ́.

ILÉ ÌṢỌ́ (ẹ̀yìn ìwé)

Béèrè ìbéèrè: Kí lèrò rẹ nípa ìbéèrè yìí? [Ka ìbéèrè àkọ́kọ́.] Àwọn kan gbà gbọ́ pé ẹni tó bá ti kú á lọ máa gbé ní ibòmíì, àwọn kan sì gbà pé ìkú ni òpin ohun gbogbo. Kí ni ìwọ gbà gbọ́?

Ka Bíbélì: Onw 9:5

Fi ìwé lọni: Àpilẹ̀kọ yìí ṣàlàyé púpọ̀ sí i nípa ohun tí Bíbélì sọ lórí kókó yìí. Màá fẹ́ kó o kà á. A máa sọ̀rọ̀ nípa rẹ̀ tí mo bá pa dà wá.

ÌRÒYÌN AYỌ̀ LÁTỌ̀DỌ̀ ỌLỌ́RUN!

Àwòrán iwájú ìwé Ìròyìn Ayọ̀ Látọ̀dọ̀ Ọlọ́run!

Fi ìwé lọni: Mo fẹ́ fi bá a ṣe máa ń ṣe ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì lọ́fẹ̀ẹ́ hàn ọ́. Ìwé pẹlẹbẹ yìí sọ ibi tí wàá ti rí ìdáhùn sáwọn ìbéèrè pàtàkì nínú Bíbélì rẹ.

Béèrè ìbéèrè: Ǹjẹ́ o ti ka Bíbélì rí? Jẹ́ kí n fi bí àwọn ẹ̀kọ́ inú ìwé yìí ṣe rọrùn tó hàn ọ́. [Bá a jíròrò ìbéèrè 1 nínú ẹ̀kọ́ 2.]

Ka Bíbélì: Iṣi 4:11

KỌ Ọ̀NÀ ÌGBỌ́RỌ̀KALẸ̀ RẸ

Wo àwọn ọ̀nà ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ tá a fi ṣe àpẹẹrẹ yìí, kó o sì kọ ọ̀nà ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ tìrẹ.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́