ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 January ojú ìwé 1
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Ìsọ̀rí
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • ILÉ ÌṢỌ́
  • MÁA FI ÒTÍTỌ́ KỌ́NI
  • ÌRÒYÌN AYỌ̀ LÁTỌ̀DỌ̀ ỌLỌ́RUN!
  • KỌ Ọ̀NÀ ÌGBỌ́RỌ̀KALẸ̀ RẸ
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 January ojú ìwé 1
Àwọn Ẹlérìí Jèhófà ń wàásù ìhìn rere ní Gánà

Wọ́n ń wàásù ìhìn rere ní Gánà

Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò

ILÉ ÌṢỌ́

Ilé Ìṣọ́ No. 1 2017 | Bó O Ṣe Lè Rí Ẹ̀kọ́ Kọ́ Látinú Kíka Bíbélì

Béèrè ìbéèrè: Àwọn kan sọ pé Bíbélì kò bágbà mu mọ́, àwọn míì sì gbà pé ó ṣì wúlò fún wa. Kí lèrò ti yín?

Ka Bíbélì: 2Ti 3:​16, 17

Fi ìwé lọni: Ìwé ìròyìn Ilé Ìṣọ́ yìí sọ díẹ̀ lára àwọn ọ̀rọ̀ ọgbọ́n tó wà nínú Bíbélì, ó sì tún sọ ohun tá a lè ṣe ká lè túbọ̀ jàǹfààní nínú Bíbélì kíkà.

MÁA FI ÒTÍTỌ́ KỌ́NI

Wọ́n ṣí Bíbélì sílẹ̀

Béèrè ìbéèrè: Ṣé òpin ayé ti sún mọ́lé?

Ka Bíbélì: Mt 24:​3, 7, 14

Òtítọ́: Àwọn àsọtẹ́lẹ̀ inú Bíbélì fi hàn pé àkókò òpin là ń gbé yìí. Ìròyìn ayọ̀ nìyẹn sì jẹ́ fún wa, torí pé ìgbà ọ̀tun máa tó wọlé dé.

ÌRÒYÌN AYỌ̀ LÁTỌ̀DỌ̀ ỌLỌ́RUN!

Ìròyìn Ayọ̀ Látọ̀dọ̀ Ọlọ́run!

Béèrè ìbéèrè: Àwọn kan ronú pé Ọlọ́run dá ayé yìí kó lè fi mọ àwọn èèyàn tó máa yege láti lọ gbé pẹ̀lú rẹ̀ ní ọ̀run, kí lèrò ti yín?

Fi ìwé lọni: Ìwé pẹlẹbẹ yìí ti ran ọ̀pọ̀ èèyàn lọ́wọ́ láti mọ̀ pé Ọlọ́run dá ayé yìí káwọn èèyàn lè máa gbé inú rẹ̀ títí láé. Màá fẹ́ pa dà wá ká lè jọ sọ̀rọ̀ lórí ìbéèrè àkọ́kọ́ lójú ìwé 10, tó sọ pé: “Kí nìdí tí Ọlọ́run fi dá ayé yìí?”

KỌ Ọ̀NÀ ÌGBỌ́RỌ̀KALẸ̀ RẸ

Wo àwọn ọ̀nà ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ tá a fi ṣe àpẹẹrẹ yìí, kó o sì kọ ọ̀nà ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ tìrẹ.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́