ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb17 April ojú ìwé 1
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Ìsọ̀rí
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • JÍ!
  • MÁA FI ÒTÍTỌ́ KỌ́NI
  • KÍ NI ÌJỌBA ỌLỌ́RUN? (Ìpadàbẹ̀wò)
  • KỌ Ọ̀NÀ ÌGBỌ́RỌ̀KALẸ̀ RẸ
  • Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀
    Jí!—2017
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
mwb17 April ojú ìwé 1
Tayọ̀tayọ̀ ni àwọn ará fi ń kí arábìnrin aláìṣiṣẹ́mọ́ kan káàbọ̀ sí ìjọ

Àwọn ará ń kí arábìnrin kan káàbọ̀ sínú Gbọ̀ngàn Ìjọba

Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò

JÍ!

Jí! No. 2 2017 | Ohun Tó Yẹ Kó o Mọ̀ Nípa Agbára Abàmì?

Béèrè ìbéèrè: Lóde òní, àwọn èèyàn máa ń ṣe fíìmù àtàwọn ètò orí tẹlifíṣọ̀n nípa agbára abàmì, bí àwọn oṣó, àwọn àjẹ́ àtàwọn iwin. Ṣẹ́ ẹ rò pé irú àwọn fíìmù bí èyí léwu fún wa àbí eré lásán náà ni?

Fi ìwé lọni: Ìwé ìròyìn Jí! yìí sọ ìdí tí ọ̀rọ̀ nípa agbára abàmì fi gba àwọn èèyàn lọ́kàn tó bẹ́ẹ̀ àti ẹni tó ń dárí àwọn ohun abàmì náà.

MÁA FI ÒTÍTỌ́ KỌ́NI

Wọ́n ṣí Bíbélì sílẹ̀

Béèrè ìbéèrè: Báwo ni Ìjọba Ọlọ́run ṣe máa yanjú ìṣòro aráyé?

Ka Bíbélì: Mt 6:10

Òtítọ́: Tí Ìjọba Ọlọ́run bá bẹ̀rẹ̀ sí í ṣàkóso láyé, àlàáfíà, ìṣọ̀kan àti ààbò máa wà lórí ilẹ̀ ayé, gẹ́gẹ́ bó ṣe wà lọ́run.

KÍ NI ÌJỌBA ỌLỌ́RUN? (Ìpadàbẹ̀wò)

Kí Ni Ìjọba Ọlọ́run?

Béèrè ìbéèrè: [Sọ̀rọ̀ nípa àwọn ìbéèrè tó wà lẹ́yìn ìwé àṣàrò kúkúrú náà.] Báwo ni ìgbésí ayé ṣe máa rí nígbà tí Ìjọba Ọlọ́run bá ń ṣàkóso?

Ka Bíbélì: Sm 37:29; Ais 65:21-23

Fi ìwé lọni: [Fi ìwé pẹlẹbẹ Ìròyìn Ayọ̀ han onílé.] Ẹ̀kọ́ 7 nínú ìwé yìí sọ àǹfààní témi àtẹ̀yin máa rí nígbà tí Ọlọ́run bá mú àwọn ìlérí yìí ṣẹ. [Fi ìwé pẹlẹbẹ náà bẹ̀rẹ̀ ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì.]

KỌ Ọ̀NÀ ÌGBỌ́RỌ̀KALẸ̀ RẸ

Wo àwọn ọ̀nà ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ tá a fi ṣe àpẹẹrẹ yìí, kó o sì kọ ọ̀nà ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ tìrẹ.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́