ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb16 February ojú ìwé 1
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Ìsọ̀rí
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • JÍ!
  • JÍ!
  • TẸ́TÍ SÍ ỌLỌ́RUN
  • KỌ Ọ̀NÀ ÌGBỌ́RỌ̀KALẸ̀ RẸ
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2017)
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
mwb16 February ojú ìwé 1
Àwọn arábìnrin kan ń fi ìwé Tẹ́tí sí Ọlọ́run lọni ní orílẹ̀-èdè Indonesia

Àwọn arábìnrin kan ń fi ìwé Tẹ́tí sí Ọlọ́run lọni ní orílẹ̀-èdè Indonesia

Àwọn Ọ̀nà Ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ Tá A Lè Lò

JÍ!

Ìwé ìròyìn Jí!, No. 1 2016 | Ṣé Ìsìn ti Fẹ́ Kógbá Wọlé?

Béèrè ìbéèrè: Ọ̀pọ̀ èèyàn máa ń ṣe kàyéfì nípa ìwà àgàbàgebè àtàwọn ẹ̀kọ́ èké tó wà nínú ọ̀pọ̀ ẹ̀sìn. Kí lẹ rò pé ó máa ṣẹlẹ̀ sí ìsìn lọ́jọ́ iwájú?

Ka Bíbélì: Iṣi 18:8

Fi ìwé lọni: Ìwé ìròyìn Jí! yìí sọ̀rọ̀ nípa bí àwọn èèyàn á ṣe kúrò nínú ìsìn èké àti bí Ọlọ́run ṣe máa pa ìsìn èké run pátápátá. [Fi àpilẹ̀kọ tó wà lójú ìwé 3 sí 6 han onílé.]

JÍ!

Béèrè ìbéèrè: Kí lẹ rò pé ó máa jẹ́ kí tọkọtaya lè gbé pọ̀ ní àlàáfíà?

Ka Bíbélì: Kol 3:13

Fi ìwé lọni: Àpilẹ̀kọ yìí sọ púpọ̀ sí i nípa bí àwọn tọkọtaya ṣe lè máa gbé pọ̀ ní àlàáfíà. [Fi àpilẹ̀kọ tó wà lójú ìwé 12 àti 13 han onílé.]

TẸ́TÍ SÍ ỌLỌ́RUN

Ìwé Tẹ́tí sí Ọlọ́run

Béèrè ìbéèrè: Ṣé ẹ máa fẹ́ gbé nínú ayé tó rí bí èyí? [Fi ojú ìwé 2 àti 3 han onílé, kó o sì jẹ́ kó fèsì.]

Ka Bíbélì: Jer 29:11

Fi ìwé lọni: Ìwé yìí sọ bí a ṣe lè tẹ́tí sí Ọlọ́run ká sì gbádùn àwọn ìbùkún tó ní fún wa lọ́jọ́ iwájú. [Bá onílé jíròrò ojú ìwé 4 àti 5.]

KỌ Ọ̀NÀ ÌGBỌ́RỌ̀KALẸ̀ RẸ

Wo àwọn ọ̀nà ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ tá a fi ṣe àpẹẹrẹ yìí, kó o sì kọ ọ̀nà ìgbọ́rọ̀kalẹ̀ tìrẹ.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́