ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb18 May ojú ìwé 4
  • Ìran Tó Ń Fún Ìgbàgbọ́ Lókun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ìran Tó Ń Fún Ìgbàgbọ́ Lókun
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Bi Ipalarada Kristi Ṣe Nipa Lori Rẹ
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1991
  • Ìran Ìyípadà Ológo
    Jésù—Ọ̀nà, Òtítọ́ Àti Ìyè
  • Kristi Làwọn Àsọtẹ́lẹ̀ Tọ́ka Sí
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2005
  • Máa Fiyè Sí Ọ̀rọ̀ Àsọtẹ́lẹ̀ Ọlọ́run
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2000
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
mwb18 May ojú ìwé 4

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | MÁÀKÙ 9-10

Ìran Tó Ń Fún Ìgbàgbọ́ Lókun

9:1-7

Pétérù, Jákọ́bù àti Jòhánù rí ìran ológo náà

Wo bó ṣe máa rí lára Jésù nígbà tó gbọ́ tí Baba rẹ̀ ọ̀run kéde nínú ìran ológo náà pé òun ti tẹ́wọ́ gbà á. Ó dájú pé ohun tí Ọlọ́run ṣe yìí fún Jésù lókun láti fara da ìyà tó máa tó jẹ. Bákan náà, ìran yìí tún ní ipa tó lágbára lórí Pétérù, Jákọ́bù àti Jòhánù. Ìran náà jẹ́ kó dá wọn lójú pé Jésù ni Mèsáyà lóòótọ́ àti pé ó dáa bí àwọn ṣe fetí sí i. Ní ọdún méjìlélọ́gbọ̀n [32] lẹ́yìn náà, Pétérù ṣì rántí ohun tó rí yẹn àti bí ìran náà ṣe jẹ́ kí ìgbàgbọ́ rẹ̀ nínú “ọ̀rọ̀ àsọtẹ́lẹ̀” náà túbọ̀ lágbára sí i.​—2Pe 1:16-19.

Bó tilẹ̀ jẹ́ pé a kò fojú rí ìran ológo yẹn, à ń rí bó ṣe ń ní ìmúṣẹ. Jésù ti ń ṣàkóso gẹ́gẹ́ bí Ọba alágbára. Láìpẹ́, Jésù máa “parí ìṣẹ́gun rẹ̀,” èyí tó máa jẹ́ kí ayé tuntun òdodo wọlé dé.​—Iṣi 6:2.

Báwo ni àsọtẹ́lẹ̀ Bíbélì tó o rí tó ń ṣẹ ṣe fún ìgbàgbọ́ rẹ lókun?

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́