ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb18 July ojú ìwé 4
  • Àpèjúwe Ará Samáríà

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àpèjúwe Ará Samáríà
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Kí Ló Túmọ̀ Sí Láti Jẹ́ “Aláàánú Ará Samáríà”?
    Ohun Tí Bíbélì Sọ
  • Ará Samáríà Kan Jẹ́ Aládùúgbò Rere
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1998
  • Àpèjúwe Ọmọ Tó Sọ Nù
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
  • Ṣé Wàá “Máa Bá A Nìṣó Ní Ṣíṣọ́nà”?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2015
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
mwb18 July ojú ìwé 4
Ará Samáríà ń de ojú ọgbẹ́ Júù kan táwọn olè dá lọ́nà

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | LÚÙKÙ 10-11

Àpèjúwe Ará Samáríà

10:25-37

Jésù sọ àpèjúwe yìí nígbà tó ń dáhùn ìbéèrè tẹ́nì kan bí i pé, “Ní ti gidi ta ni aládùúgbò mi?” (Lk 10:​25-29) Jésù mọ̀ pé tó bá yá “onírúurú ènìyàn gbogbo” ló máa wà nínú ìjọ Kristẹni, tó fi mọ́ àwọn ará Samáríà àtàwọn Kèfèrí. (Jo 12:32) Àpèjúwe yìí kọ́ àwọn ọmọlẹ́yìn rẹ̀ pé wọ́n ní láti sa gbogbo ipá wọn láti fìfẹ́ hàn sí àwọn èèyàn, títí kan àwọn tó ṣeé ṣe kó yàtọ̀ sí wọn pàápàá.

Àwọn èèyàn tó wá láti orílẹ̀-èdè ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ jọ wà níbi àpèjẹ

BI ARA RẸ PÉ:

  • ‘Ojú wo ni mo fi ń wo àwọn arákùnrin àtàwọn arábìnrin tí àṣà ìbílẹ̀ wọn yàtọ̀ sí tèmi?’

  • ‘Ṣé àwọn tí ọ̀rọ̀ wa jọra nìkan ni mo máa ń bá da nǹkan pọ̀?’

  • ‘Ṣé mo lè gbòòrò síwájú nípa títúbọ̀ mọ àwọn ará tí ọ̀nà tí wọ́n gbà tọ́ wọn dàgbà yàtọ̀ sí tèmi?’ (2Kọ 6:13)

Mo fẹ́ pe

  • ká jọ ṣiṣẹ́ lóde ẹ̀rí

  • kó wá bá wa jẹun

  • kó wá bá wa ṣe Ìjọsìn Ìdílé

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́