ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb18 July ojú ìwé 6
  • Àpèjúwe Ọmọ Tó Sọ Nù

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Àpèjúwe Ọmọ Tó Sọ Nù
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Àpèjúwe Ará Samáríà
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
  • Bàbá Kan Tí Ó Ṣe Tán Láti Dárí Jini
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1997
  • Ṣé Wàá “Máa Bá A Nìṣó Ní Ṣíṣọ́nà”?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2015
  • Ẹ Wà Lójúfò, Kí Ẹ Sì Jẹ́ Aláápọn!
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1999
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
mwb18 July ojú ìwé 6
Bàbá ọmọ onínàákúnàá gbà á pa dà sílé

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | LÚÙKÙ 14-16

Àpèjúwe Ọmọ Tó Sọ Nù

15:11-32

Díẹ̀ lára àwọn ẹ̀kọ́ tá a rí kọ́ látinú àpèjúwe yìí.

  • Ìwà ọgbọ́n ló jẹ́ tá a bá dúró síbi ààbò lọ́dọ̀ àwọn èèyàn Ọlọ́run, níbi tí Baba wa ọ̀run ti ń bójú tó wa

  • Tá a bá yà kúrò ní ọ̀nà Ọlọ́run, ó yẹ ká fìrẹ̀lẹ̀ pa dà, ká sì ní ìdánilójú pé Jèhófà máa dárí jì wá

  • A gbọ́dọ̀ tẹ̀ lé àpẹẹrẹ Jèhófà, ká máa fi tinútinú gba àwọn tó ronú pìwà dà, tí wọ́n sì pa dà wá sínú ìjọ

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́