ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb20 February ojú ìwé 4
  • Kí Nìdí Tí Jèhófà Fi Yí Orúkọ Ábúrámù àti Sáráì Pa Dà?

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Kí Nìdí Tí Jèhófà Fi Yí Orúkọ Ábúrámù àti Sáráì Pa Dà?
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ní Irú Ìgbàgbọ́ Tí Ábúráhámù Ní!
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2001
  • “Baba Gbogbo Àwọn Tí Wọ́n Ní Ìgbàgbọ́”
    Tẹ̀ Lé Àpẹẹrẹ Ìgbàgbọ́ Wọn
  • Ábúráhámù—Àpẹẹrẹ Ìgbàgbọ́
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2001
  • Ọlọ́run Pè É Ní “Ìyá Ọba”
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tá À Ń Fi Sóde)—2017
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
mwb20 February ojú ìwé 4

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | JẸ́NẸ́SÍSÌ 15-17

Kí Nìdí Tí Jèhófà Fi Yí Orúkọ Ábúrámù àti Sáráì Pa Dà?

17:1, 3-5, 15, 16

Jèhófà ka Ábúrámù sí aláìlẹ́bi. Ó sì fún Ábúrámù àti Sáráì ní orúkọ tó máa jẹ́ kí ìlérí tó ṣe fún wọn túbọ̀ dá wọn lójú.

Orúkọ náà sì rò wọ́n lóòótọ́, torí pé Ábúráhámù di bàbá ọ̀pọ̀ orílẹ̀-èdè, Sérà sì di ìyá àwọn ọba.

  • Ábúráhámù.

    Ábúráhámù

    Bàbá Ọ̀pọ̀ Èèyàn

  • Sérà.

    Sérà

    Ìyá Àwọn Ọba

Àwọn àwòrán: Arábìnrin kan ń tẹ̀ síwájú nípa tẹ̀mí. 1. Ó ń ṣèrìbọmi. 2. Ó ń ṣiṣẹ́ ní ìpàdé àárín ọ̀sẹ̀. 3. Ó ń fi fídíò han obìnrin kan lóde ẹ̀rí.

A ò lè yan orúkọ tí wọ́n máa sọ wá nígbà tí wọ́n bí wa. Ṣùgbọ́n bíi ti Ábúráhámù àti Sérà, a lè ṣe orúkọ rere fún ara wa. Bi ara rẹ pé:

  • ‘Báwo ni mo ṣe lè jẹ́ aláìlẹ́bi lójú Jèhófà?’

  • ‘Irú orúkọ wo ni mò ń ṣe fún ara mi lọ́dọ̀ Jèhófà?’

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́