ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb20 July ojú ìwé 6
  • Ohun Tí Ìrékọjá Túmọ̀ sí fún Àwa Kristẹni

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ohun Tí Ìrékọjá Túmọ̀ sí fún Àwa Kristẹni
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Kí Ni Ìrékọjá?
    Ohun Tí Bíbélì Sọ
  • Ìyọnu Kẹwàá
    Àwọn Ẹ̀kọ́ Tó O Lè Kọ́ Látinú Bíbélì
  • ‘Èyí Yóò Jẹ́ Ìrántí Fún Yín’
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2013
  • Ìyàtọ̀ àti Ìjọra Tó Wà Láàárín Ìrékọjá àti Ìrántí Ikú Kristi
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2018
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
mwb20 July ojú ìwé 6
Ìdílé kan lára àwọn ọmọ Ísírẹ́lì ń jẹ oúnjẹ Ìrékọjá náà kí wọ́n tó kúrò ní Íjíbítì.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | Ẹ́KÍSÓDÙ 12

Ohun Tí Ìrékọjá Túmọ̀ sí fún Àwa Kristẹni

12:5-7, 12, 13, 24-27

Káwọn ọmọ Ísírẹ́lì má bàa fara gbá ìyọnu kẹwàá, ó ṣe pàtàkì pé kí wọ́n tẹ̀ lé àwọn ìtọ́ni pàtó kan. (Ẹk 12:28) Ní alẹ́ Nísàn 14, Mósè fún ìdílé kọ̀ọ̀kan ní ìtọ́ni pé kí wọ́n wà nínú ilé wọn. Kí wọ́n pa ọ̀dọ́ àgùntàn ọlọ́dún kan tàbí ewúrẹ́ tára ẹ̀ dá ṣáṣá, kí wọ́n sì wọ́n ẹ̀jẹ́ rẹ̀ sára àwọn òpó ilẹ̀kùn àti apá òkè ẹnu ọ̀nà. Lẹ́yìn náà, kí wọ́n yan gbogbo ẹran náà nínú iná, kí wọ́n sì yára jẹ ẹ́. Ẹnì kankan ò gbọ́dọ̀ jáde nínú ilé rẹ̀ títí ilẹ̀ fi máa mọ́.​—Ẹk 12:9-11, 22.

Àwọn ọ̀nà pàtó wo ni ìgbọ́ràn gbà ń dáàbò bò wá lónìí?

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́