ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb20 November ojú ìwé 3
  • Ìdí Tí Wọ́n Fi Ń Mú Ọrẹ Wá

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ìdí Tí Wọ́n Fi Ń Mú Ọrẹ Wá
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Àwọn Ẹbọ Ìyìn Tí Inú Jèhófà Dùn Sí
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2000
  • Àwọn Ẹbọ Tí Inú Ọlọ́run Dùn Sí
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2000
  • Bá A Ṣe Lè Máa Rú Àwọn Ẹbọ Tí Inú Ọlọ́run Dùn Sí
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2007
  • Kẹ́kọ̀ọ́ Látinú ‘Kókó Òtítọ́’
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2012
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2020
mwb20 November ojú ìwé 3
Àwòrán: 1. Màlúù, àgùntàn àti ewúrẹ́ tí wọ́n fẹ́ fi rúbọ. 2. Jésù wà lórí òpó igi oró.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | LÉFÍTÍKÙ 1-3

Ìdí Tí Wọ́n Fi Ń Mú Ọrẹ Wá

1:3; 2:1, 12; 3:1

Ẹbọ táwọn ọmọ Ísírẹ́lì ń rú máa ń múnú Jèhófà dùn, ó sì ń ṣàpẹẹrẹ ìràpadà tí Jésù san láti ṣe aráyé láǹfààní.​—Heb 8:3-5; 9:9; 10:5-10.

  • Ẹran tára ẹ̀ dá ṣáṣá ni wọ́n gbọ́dọ̀ fi rúbọ, bẹ́ẹ̀ náà ni ìràpadà Jésù ṣe pé, tí kò sì lábàwọ́n.​—1Pe 1:​18, 19

  • Tẹ́nì kan bá fẹ́ fi ẹran kan rú ẹbọ sísun, ṣe ló máa fún Jèhófà ní gbogbo ẹ̀ pátápátá, bẹ́ẹ̀ ni Jésù ṣe fi gbogbo ara ẹ̀ rúbọ fún Jèhófà

  • Kí Jèhófà tó lè tẹ́wọ́ gba ẹbọ ìrẹ́pọ̀ lọ́wọ́ ẹnì kan, ẹni náà gbọ́dọ̀ ní àjọṣe tó dáa pẹ̀lú rẹ̀, bẹ́ẹ̀ náà làwọn ẹni àmì òróró tó máa ń jẹ́ ohun ìṣàpẹẹrẹ níbi Ìrántí Ikú Kristi ṣe ní àjọṣe tó dáa pẹ̀lú Ọlọ́run

Arákùnrin kan tó jẹ́ ẹni àmì òróró ń jẹ ohun ìṣàpẹẹrẹ nígbà Ìrántí Ikú Kristi.
    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́