ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb21 November ojú ìwé 8
  • Jèhófà Gba Àwọn Èèyàn Rẹ̀ Là Nípasẹ̀ Àwọn Obìnrin Méjì

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Jèhófà Gba Àwọn Èèyàn Rẹ̀ Là Nípasẹ̀ Àwọn Obìnrin Méjì
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • “O Ò Gbọ́dọ̀ Bá Wọn Dána Rárá”
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Fara Wé Èlíṣà Tí Wọ́n Bá Ń Dá Ẹ Lẹ́kọ̀ọ́
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
  • ‘Mo Dìde Gẹ́gẹ́ Bí Ìyá ní Ísírẹ́lì’
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2015
  • Àwọn Obìnrin Méjì Tó Nígboyà
    Ìwé Ìtàn Bíbélì
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
mwb21 November ojú ìwé 8
Dèbórà tó jẹ́ wòlíì obìnrin jókòó sábẹ́ igi ọ̀pẹ, ó ń fún Bárákì níṣìírí pé kó ran àwọn èèyàn Ọlọ́run lọ́wọ́.

Dèbórà ń sọ fún Bárákì pé kó ran àwọn èèyàn Ọlọ́run lọ́wọ́

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Jèhófà Gba Àwọn Èèyàn Rẹ̀ Là Nípasẹ̀ Àwọn Obìnrin Méjì

Ọ̀tá tó lágbára fòòró ẹ̀mí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì (Ond 4:3; 5:6-8; w15 8/1 12 ¶6)

Jèhófà yan Dèbórà pé kó ran àwọn èèyàn òun lọ́wọ́ (Ond 4:4-7; 5:7; w15 8/1 13 ¶1; wo àwòrán iwájú ìwé)

Jèhófà mú kí Jáẹ́lì pa Sísérà (Ond 4:16, 17, 21; w15 8/1 15 ¶2)

Àwòrán: 1. Dèbórà jókòó sábẹ́ igi ọ̀pẹ, ó ń fún Bárákì níṣìírí pé kó ran àwọn èèyàn Ọlọ́run lọ́wọ́. 2. Sísérà ti sùn lọ fọnfọn, Jáẹ́lì sì mú èèkàn àgọ́ àti òòlù dání lẹ́gbẹ̀ẹ́ etí rẹ̀.

Kí la rí kọ́ nínú ìtàn yìí nípa ojú tí Jèhófà fi ń wo àwọn obìnrin?

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́