ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb22 May ojú ìwé 9
  • Dáfídì Fi Ìfẹ́ Tí Kì Í Yẹ̀ Hàn

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Dáfídì Fi Ìfẹ́ Tí Kì Í Yẹ̀ Hàn
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ǹjẹ́ Ó Máa Ń Ṣe Ẹ́ Bíi Pé Àjèjì Ni Ẹ́?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2011
  • Máa Ṣe Ohun Tí Jèhófà Fẹ́ Nígbà Gbogbo
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
  • Ìbéèrè Láti Ọwọ́ Àwọn Òǹkàwé
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2022
  • Wọ́n Fara Da Ẹ̀gún Nínú Ẹran Ara Wọn
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2002
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2022
mwb22 May ojú ìwé 9

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Dáfídì Fi Ìfẹ́ Tí Kì Í Yẹ̀ Hàn

Dáfídì wá ẹni tó lè fìfẹ́ tí kì í yẹ̀ hàn sí nínú ilé Sọ́ọ̀lù (2Sa 9:1; w06 6/15 14 ¶6)

Dáfídì gbé ìgbésẹ̀ láti ran Mefibóṣétì lọ́wọ́ láìjáfara (1Sa 20:15, 42; 2Sa 9:5-7; w05 5/15 17 ¶12)

Dáfídì ní kí Síbà máa bójú tó ogún Mefibóṣétì (2Sa 9:9, 10; w02 2/15 14 ¶10)

Arábìnrin àgbàlagbà kan ń gbá arábìnrin ọ̀dọ́ kan mọ́ra, ó sì ń tù ú nínú.

Dáfídì ò gbàgbé ìlérí tó ṣe fún Jónátánì. Ó yẹ káwa náà máa fìfẹ́ tí kì í yẹ̀ hàn sáwọn ará wa.​—Sm 41:1, 2; Owe 19:17.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́