ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb23 March ojú ìwé 12
  • Tá A Bá Tẹ̀ Lé Ìmọ̀ràn Tó Dáa Ó Máa Ṣe Wá Láǹfààní

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Tá A Bá Tẹ̀ Lé Ìmọ̀ràn Tó Dáa Ó Máa Ṣe Wá Láǹfààní
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ó Pàdánù Ojú Rere Ọlọ́run
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2018
  • Kí Nìdí Tó Fi Yẹ Kó O Máa Gbàmọ̀ràn Lọ́dọ̀ Àwọn Èèyàn?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2025
  • “Ọkàn Mi Á Máa Wà Níbẹ̀ Nígbà Gbogbo”
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Ọba Sólómọ́nì Ṣe Ìpinnu Tí Ò Mọ́gbọ́n Dání
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
mwb23 March ojú ìwé 12

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Tá A Bá Tẹ̀ Lé Ìmọ̀ràn Tó Dáa Ó Máa Ṣe Wá Láǹfààní

Rèhóbóámù dojú kọ ipò tó gba pé kó ṣèpinnu (2Kr 10:1-4; w18.06 13 ¶3)

Rèhóbóámù ní káwọn míì gba òun nímọ̀ràn (2Kr 10:6-11; w01 9/1 28-29)

Rèhóbóámù kọ ìmọ̀ràn tó dáa tí wọ́n fún un, ìyẹn sì mú kí ìyà jẹ òun àti àwọn èèyàn náà (2Kr 10:12-16; it-2 768 ¶1)

Arábìnrin ọ̀dọ́ kan ń tẹ́tí sí arábìnrin àgbàlagbà kan bó ṣe ń sọ̀rọ̀ nílé oúnjẹ.

Àwọn àgbàlagbà tí òtítọ́ jinlẹ̀ nínú wọn tí wọ́n sì ní ìrírí máa ń mọ ibi tó ṣeé ṣe kí ọ̀rọ̀ kan já sí.​—Job 12:12.

BI ARA RẸ PÉ, ‘Àwọn wo nínú ìjọ ló lè fún mi ní ìmọ̀ràn tó dáa?’

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́