ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb23 May ojú ìwé 4
  • “Ẹ Ní Ìgbàgbọ́ Nínú Jèhófà Ọlọ́run Yín”

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • “Ẹ Ní Ìgbàgbọ́ Nínú Jèhófà Ọlọ́run Yín”
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Máa Fi Ojú Tí Jèhófà Fi Ń Wo Àwọn Èèyàn Wò Wọ́n
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Ìgbà Wo Ló Yẹ Ká Gbẹ́kẹ̀ Lé Jèhófà?
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • “Ọkàn Mi Á Máa Wà Níbẹ̀ Nígbà Gbogbo”
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • B8 Tẹ́ńpìlì Tí Sólómọ́nì Kọ́
    Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
mwb23 May ojú ìwé 4

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

“Ẹ Ní Ìgbàgbọ́ Nínú Jèhófà Ọlọ́run Yín”

Nígbà táwọn ọ̀tá ń halẹ̀, Jèhóṣáfátì àtàwọn èèyàn Júdà bẹ Jèhófà pé kó ran àwọn lọ́wọ́ (2Kr 20:12, 13; w14 12/15 23 ¶8)

Jèhófà fi àwọn èèyàn náà lọ́kàn balẹ̀, ó sì fún wọn ní ìtọ́ni tó ṣe kedere (2Kr 20:17)

Jèhófà gba àwọn èèyàn ẹ̀ sílẹ̀ torí wọ́n gbẹ́kẹ̀ lé e (2Kr 20:21, 22, 27; w21.11 16 ¶7)

Àwọn ọlọ́pàá tó dira ogun já wọnú ilé táwọn Ẹlẹ́rìí Jèhófà mélòó kan ti ń ṣèpàdé.

Tí Gọ́ọ̀gù bá gbéjà ko àwa èèyàn Jèhófà nígbà ìpọ́njú ńlá, àwọn tó bá gbẹ́kẹ̀ lé Jèhófà tí wọ́n sì ń tẹ̀ lé ìtọ́ni àwọn tó yàn láti máa ṣàbójútó kò ní bẹ̀rù ohunkóhun.​—2Kr 20:20.

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́