ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb23 July ojú ìwé 14
  • Jẹ́ Adúróṣinṣin sí Jèhófà Tó O Bá Fẹ́ Yan Ọ̀rẹ́

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Jẹ́ Adúróṣinṣin sí Jèhófà Tó O Bá Fẹ́ Yan Ọ̀rẹ́
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Àwọn Ẹ̀kọ́ Tí A Rí Kọ́ Lára Nehemáyà
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • A Ti Sọ Yín Di Mímọ́
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2013
  • Máa Fún Àwọn Míì Níṣìírí Nígbà Ìṣòro
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • “Ìdùnnú Jèhófà Ni Ibi Ààbò Yín”
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
mwb23 July ojú ìwé 14
Nehemáyà da àwọn ẹrù Tobáyà síta yàrá ìjẹun tẹ́ńpìlì.

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Jẹ́ Adúróṣinṣin sí Jèhófà Tó O Bá Fẹ́ Yan Ọ̀rẹ́

Òfin Ọlọ́run sọ pé àwọn ọmọ Ámónì àti àwọn ọmọ Móábù kò gbọ́dọ̀ “wá sínú ìjọ” torí pé wọ́n ti fìgbà kan rí ta ko àwọn èèyàn Ọlọ́run (Ne 13:1, 2; it-1 95 ¶5)

Élíáṣíbù Àlùfáà Àgbà fún ọmọ Ámónì kan láyè láti máa lo yàrá ìjẹun tó wà nínú tẹ́ńpìlì (Ne 13:4, 5; w13 8/15 4 ¶5-6)

Nehemáyà fi hàn pé òun jẹ́ adúróṣinṣin sí Jèhófà, ó sì da gbogbo ẹrù ọ̀tá Jèhófà náà síta (Ne 13:7-9)

Tá a bá yan àwọn tí kò nífẹ̀ẹ́ Jèhófà lọ́rẹ̀ẹ́, ṣé ìyẹn á fi hàn pé a jẹ́ adúróṣinṣin sí Jèhófà?​—w96 3/15 16 ¶6.

BI ARA RẸ PÉ, ‘Ṣé inú Jèhófà máa dùn sí irú àwọn ọ̀rẹ́ tí mò ń bá rìn yìí?

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́