ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb23 May ojú ìwé 11
  • Máa Fún Àwọn Míì Níṣìírí Nígbà Ìṣòro

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Máa Fún Àwọn Míì Níṣìírí Nígbà Ìṣòro
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Bó O Ṣe Lè Mú Kí Ọ̀nà Rẹ Yọrí Sí Rere
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Yẹra fún Ojúsàájú, Kó O Lè Fìwà Jọ Jèhófà
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Jèhófà Máa Ń Bù Kún Àwọn Tó Nígbàgbọ́
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • “Ẹ Ní Ìgbàgbọ́ Nínú Jèhófà Ọlọ́run Yín”
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2023
mwb23 May ojú ìwé 11

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN

Máa Fún Àwọn Míì Níṣìírí Nígbà Ìṣòro

Senakérúbù gbógun ja ilẹ̀ Júdà, ó sì lérí pé òun máa gba Jerúsálẹ́mù (2Kr 32:1; it-1 204 ¶5)

Hẹsikáyà ṣe gbogbo ohun tó yẹ láti dáàbò bo Jerúsálẹ́mù (2Kr 32:2-5; w13 11/15 19 ¶12)

Hẹsikáyà fún àwọn èèyàn náà níṣìírí (2Kr 32:6-8; w13 11/15 19 ¶13)

Àwọn arákùnrin ń gbé oúnjẹ àtàwọn nǹkan míì wá fún ìyá kan àti ọmọbìnrin ẹ̀.

BI ARA RẸ PÉ, ‘Báwo ni mo ṣe lè ran àwọn tá a jọ ń sin Jèhófà lọ́wọ́ nígbà ìṣòro?’

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́