ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • yb16 ojú ìwé 25-ojú ìwé 27 ìpínrọ̀ 1
  • Ìmọ́lẹ̀ Ń Mọ́lẹ̀ Sí I

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Ìmọ́lẹ̀ Ń Mọ́lẹ̀ Sí I
  • Ìwé Ọdọọdún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà—2016
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Bó O Ṣe Lè Mú Kí Ọ̀nà Rẹ Yọrí Sí Rere
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Yẹra fún Ojúsàájú, Kó O Lè Fìwà Jọ Jèhófà
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
  • Ǹjẹ́ O Rántí?
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́)—2016
  • “O Ò Gbọ́dọ̀ Bá Wọn Dána Rárá”
    Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Kristẹni—Ìwé Ìpàdé—2021
Àwọn Míì
Ìwé Ọdọọdún Àwa Ẹlẹ́rìí Jèhófà—2016
yb16 ojú ìwé 25-ojú ìwé 27 ìpínrọ̀ 1
Àwọn òṣìṣẹ́ nínú oko àlìkámà

ÀWỌN OHUN PÀTÀKÌ TÓ ṢẸLẸ̀ LỌ́DÚN TÓ KỌJÁ

Ìmọ́lẹ̀ Ń Mọ́lẹ̀ Sí I

TORÍ pé àwọn ìránṣẹ́ Jèhófà mọ̀ pé Jèhófà ni Orísun ìmọ́lẹ̀ tẹ̀mí tàbí pé Òun ló lè jẹ́ káwọn lóye Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, wọ́n máa ń gbàdúrà pé kí Ọlọ́run ‘ìmọ́lẹ̀ àti òtítọ́’ máa tọ́ àwọn sọ́nà, kó sì máa darí àwọn. (Sm. 43:⁠3) Bí ayé yìí ṣe túbọ̀ ń jìn sínú òkùnkùn birimùbirimù, ṣe ni Jèhófà túbọ̀ ń jẹ́ kí ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ máa ṣamọ̀nà àwa èèyàn rẹ̀. Èyí wá mú kí ipa ọ̀nà wa “dà bí ìmọ́lẹ̀ mímọ́lẹ̀ yòò, tí ń mọ́lẹ̀ síwájú àti síwájú sí i.” (Òwe 4:18) Bí Jèhófà ṣe túbọ̀ ń fi ìmọ́lẹ̀ rẹ̀ ṣamọ̀nà wa ti mú kí ọ̀nà tá a gbà ṣètò àwọn nǹkan túbọ̀ dára sí i, bẹ́ẹ̀ sì làwọn ẹ̀kọ́ tá à ń kọ́ àti ìwà wa ń sunwọ̀n sí i. Kí ni díẹ̀ lára àwọn àtúnṣe tó wáyé lẹ́nu àìpẹ́ yìí sáwọn ohun tá a gbà gbọ́?

2012

‘Gbogbo ìjọba yìí’​—Dán. 2:44

w12 6/15 ojú ìwé 17

Módékáì àti Ẹ́sítérì “pín ohun ìfiṣèjẹ”​—Jẹ́n. 49:27

w12 1/1 ojú ìwé 29

‘Ọba kan tí ó rorò ní ojú’ máa fa ìparun​—Dán. 8:23, 24

w12 6/15 ojú ìwé 16

Ọmọ ìka ẹsẹ ère inú àlá Nebukadinésárì​—Dán. 2:41-43

w12 6/15 ojú ìwé 16

Ìgbà wo ni agbára ayé keje bẹ̀rẹ̀ sí í ṣàkóso

w12 6/15 ojú ìwé 15, àti 19

2013

“Ẹrú olóòótọ́ àti olóye”​—Mát. 24:45-47

w13 7/15 ojú ìwé 8, 20 sí 25

“Ẹrú búburú”​—Mát. 24:48-51

w13 7/15 ojú ìwé 24

Àwọn ẹni àmì òróró á ti lọ sọ́run kí Amágẹ́dọ́nì tó jà

w13 7/15 ojú ìwé 5

‘Ará Ásíríà wá sí ilẹ̀ wa’​—Míkà 5:5

w13 11/15 ojú ìwé 20

A ó kó àwọn àyànfẹ́ jọ​—Mát. 24:31; Máàkù 13:27

w13 7/15 ojú ìwé 5

Ìpọ́njú ńlá

w13 7/15 ojú ìwé 3 sí 8

Àkàwé àlìkámà àti èpò​—Mát. 13:24-30

w13 7/15 ojú ìwé 13 sí 14

Jésù ń bọ̀, Jésù dé​—Mát. orí 24 àti 25

w13 7/15 ojú ìwé 7 sí 8, àti 24

Jésù ṣèbẹ̀wò sí tẹ́ńpìlì tẹ̀mí lọ́dún 1914 sí 1919​—Mál. 3:1-4

w13 7/15 ojú ìwé 11 sí 12

Ìtumọ̀ orúkọ Jèhófà

w15 12/15 ojú ìwé 10 sí 11

2014

Bí a ṣe ń yan àwọn alàgbà àtàwọn ìránṣẹ́ iṣẹ́ òjíṣẹ́

w14 11/15 ojú ìwé 28 sí 29

Ohun tó mú kí àwọn Júù ọ̀rúndún kìíní máa “fojú sọ́nà” fún Mèsáyà​—Lúùkù 3:15

w14 2/15 ojú ìwé 26 sí 27; w14 6/15 ojú ìwé 22

Bí àkókò tí wọ́n fi fọ tẹ́ńpìlì tẹ̀mí mọ́ ṣe gùn tó​—Mál. 3:1-4

w14 11/15 ojú ìwé 30

Ìgbéyàwó nígbà àjíǹde​—Lúùkù 20:34-36

w14 8/15 ojú ìwé 29 sí 30

“Ìpìlẹ̀ lílágbára ti Ọlọ́run”​—2 Tím. 2:19

w14 7/15 ojú ìwé 8 sí 9, àti 13

Ẹlẹ́rìí méjì​—Ìṣípayá orí 11

w14 11/15 ojú ìwé 30

2015

Gọ́ọ̀gù ti ilẹ̀ Mágọ́gù​—Ìsíkíẹ́lì orí 38 àti 39

w15 5/15 ojú ìwé 29-30

Ǹjẹ́ ó yẹ kí arábìnrin kan borí rẹ̀ tó bá ń darí ìkẹ́kọ̀ọ́ Bíbélì?

w15 2/15 ojú ìwé 30

Àpèjúwe nípa àwọn tálẹ́ńtì​—Mát. 25:14-30

w15 3/15 ojú ìwé 20 sí 24

Àpèjúwe àwọn wúńdíá mẹ́wàá​—Mát. 25:1-13

w15 3/15 ojú ìwé 13 sí 16

Ìdí tí a kì í fi sọ pé ohun kan nínú Bíbélì ń ṣàpẹẹrẹ nǹkan míì

w15 3/15 ojú ìwé 9 sí 11, 17 sí 18; w15 6/15 ojú ìwé 32

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́