ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • sn orin 8
  • Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa
  • Kọrin sí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • A Ti Di Ọ̀kan Ṣoṣo
    Kọrin sí Jèhófà
  • A Ti Di Ọ̀kan Ṣoṣo
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Bá A Ṣe Lè Ṣe Ọ̀nà Wa Ní Rere
    Kọrin sí Jèhófà
Àwọn Míì
Kọrin sí Jèhófà
sn orin 8

Orin 8

Oúnjẹ Alẹ́ Olúwa

Bíi Ti Orí Ìwé

(Mátíù 26:26-30)

1. Jèhófà, Baba wa ní ọ̀run,

Alẹ́ mímọ́ lèyí fún wa!

Ògo, agbára, ìfẹ́, ẹ̀tọ́, ọgbọ́n rẹ

Hàn lọ́jọ́ kẹrìnlá Nísàn.

Wọ́n jẹ àgùntàn Ìrékọjá,

Ísírẹ́lì dòmìnira.

Jésù ta ẹ̀jẹ̀ tirẹ̀ sílẹ̀ láti mú

Àsọtẹ́lẹ̀ yìí ṣẹ lẹ́yìn náà.

2. A pé jọ síwájú rẹ Baba,

Bí àgùntàn pápá tìrẹ.

Láti yìn ọ́ fún ìfẹ́ tó mú Kristi wá,

Láti bọlá fórúkọ rẹ.

Kí Ìrántí Ikú Kristi yìí

Má ṣe kúrò lọ́kàn wa láé.

Ká lè máa rìn lọ́nà tí Jésù fi hàn wá,

Ká lè rí ìyè àìnípẹ̀kun.

(Tún wo Lúùkù 22:14-20; 1 Kọ́r. 11:23-26.)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́