ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • sn orin 107
  • Wá sí Òkè Jèhófà

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Wá sí Òkè Jèhófà
  • Kọrin sí Jèhófà
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ẹ Wá sí Òkè Jèhófà
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Wá Ọlọ́run Kó O Lè Rí Ìgbàlà
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
  • Wá Ọlọ́run Kó O Lè Rí Ìgbàlà
    Kọrin sí Jèhófà
  • Máa Wàásù fún Onírúurú Èèyàn
    “Fi Ayọ̀ Kọrin” sí Jèhófà
Àwọn Míì
Kọrin sí Jèhófà
sn orin 107

Orin 107

Wá sí Òkè Jèhófà

Bíi Ti Orí Ìwé

(Aísáyà 2:2-4)

1. Gbójú wòkè réré,

Kọjá òkè tó ga jù.

Ibẹ̀ ni òkè Jáà wà

Tí a gbé ga lónìí.

Àwọn èèyàn ń wá,

Àní látibi gbogbo,

Wọ́n ń ké síra wọn pé,

‘Wá jọ́sìn Ọlọ́run.’

Àkókò tó wàyí,

Kẹ́ni kékeré di ilẹ̀ ńlá.

Báa ṣe ń gbèrú síi,

A ńrọ́wọ́ Ọlọ́run lára wa.

Èrò ńya sọ́dọ̀ rẹ̀

Wọ́n gbàá l’Ọ́ba Aláṣẹ.

Wọ́n jẹ́jẹ̀ẹ́ ìṣòtítọ́

Láìní yẹsẹ̀ láéláé.

2. Jésù ló paá láṣẹ

Pé ká wàásù ọ̀rọ̀ náà.

Ìhìn ’jọba Ọlọ́run

Ńdọ́dọ̀ gbogbo ayé.

Kristi ńjọba lọ́run,

Ó ń pe gbogbo èèyàn.

Ọlọ́kàn tútù tó ńgbọ́

Ń tẹ̀ lé Bíbélì.

Ayọ̀ gbọkàn wa pé

Ogunlọ́gọ̀ ńlá túbọ̀ ńbí síi!

Iṣẹ́ gbogbo wa ni,

Láti fọ̀nà Jèhófà hanni.

Jẹ́ ká gbóhùn sókè,

Ká ké tantan sáráyé,

‘Ẹ wá sókè Jèhófà,

Má sì kúrò níbẹ̀.’

(Tún wo Sm. 43:3; 99:9; Aísá. 60:22; Ìṣe 16:5.)

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́