ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • mwb16 October ojú ìwé 6
  • Máa Wà Ní Àlàáfíà Pẹ̀lú Àwọn Ẹlòmíì

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

  • Máa Wà Ní Àlàáfíà Pẹ̀lú Àwọn Ẹlòmíì
  • Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
  • Àpilẹ̀kọ Míì Tó Jọ ọ́
  • Ẹ Wa Alaafia Ki Ẹ Si Maa Lepa rẹ̀”
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1991
  • Ẹ Máa Lépa Àlàáfíà
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2011
  • “Máa Lépa Àwọn Ohun Tí Ń Yọrí sí Àlàáfíà”
    Ilé Ìṣọ́ Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—2008
  • Ẹ Jẹ Ki “Alaafia Ọlọrun” Maa Daabobo Ọkan-aya Yin
    Ilé-Ìṣọ́nà Tí Ń Kéde Ìjọba Jehofa—1991
Àwọn Míì
Ìgbésí Ayé àti Iṣẹ́ Òjíṣẹ́ Àwa Kristẹni​—Ìwé Ìpàdé (2016)
mwb16 October ojú ìwé 6

ÀWỌN ÌṢÚRA INÚ Ọ̀RỌ̀ ỌLỌ́RUN | ÒWE 17-21

Máa Wà Ní Àlàáfíà Pẹ̀lú Àwọn Ẹlòmíì

Obìnrin kan tó ń gbàdúrà, lẹ́yìn náà ó lọ yanjú aáwọ̀ tó wà láàárín òun àti obìnrin mí ì kí àlááfíà lè jọba

Àlááfíà tó wà láàárín àwa èèyàn Jèhófà kì í ṣe èèṣì. Tí èdèkòyédè bá ṣẹlẹ̀, ó lè múnú bí wa gan-an, àmọ́ ìmọ̀ràn inú Ọ̀rọ̀ Ọlọ́run máa ń pẹ̀tù sí wa lọ́kàn.

Tí àìgbọ́ra-ẹni-yé bá ṣẹlẹ̀, àwọn Kristẹni olóòótọ́ máa ń wá àlááfíà nípa . . .

19:⁠11

  • ṣíṣàì-fara-ya

18:13, 17

  • rírí i pé àwọn mọ gbogbo bọ́rọ̀ ṣe jẹ́ kí wọ́n tó fèsì

17:9

  • jíjẹ́ kí ìfẹ́ mú kí wọ́n dárí ji ẹni tó ṣẹ̀ wọ́n

    Yorùbá Publications (1987-2025)
    Jáde
    Wọlé
    • Yorùbá
    • Fi Ráńṣẹ́
    • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
    • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
    • Àdéhùn Nípa Lílò
    • Òfin
    • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
    • JW.ORG
    • Wọlé
    Fi Ráńṣẹ́