Sáàmù 96:10 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 10 Ẹ kéde láàárín àwọn orílẹ̀-èdè pé: “Jèhófà ti di Ọba!+ Ayé* fìdí múlẹ̀ gbọn-in gbọn-in, kò ṣeé ṣí nípò.* Òun yóò dá ẹjọ́ àwọn èèyàn* lọ́nà tí ó tọ́.”+ Sáàmù 97:1 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 97 Jèhófà ti di Ọba!+ Kí inú ayé máa dùn.+ Kí ọ̀pọ̀ erékùṣù máa yọ̀.+ Àìsáyà 52:7 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 7 Wo bí ẹsẹ̀ ẹni tó ń mú ìhìn rere wá ṣe rẹwà tó lórí àwọn òkè,+Ẹni tó ń kéde àlàáfíà,+Ẹni tó ń mú ìhìn rere wá nípa ohun tó sàn,Ẹni tó ń kéde ìgbàlà,Ẹni tó ń sọ fún Síónì pé: “Ọlọ́run rẹ ti di Ọba!”+ Ìfihàn 11:17 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 17 wọ́n ní: “A dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, Jèhófà* Ọlọ́run, Olódùmarè, ẹni tó ti wà tipẹ́, tó sì wà báyìí,+ torí o ti gba agbára ńlá rẹ, o sì ti ń jọba.+ Ìfihàn 19:6 Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun 6 Mo sì gbọ́ ohun tó dún bí ohùn àwọn tó pọ̀ gan-an àti bí ìró omi tó pọ̀ àti bí ìró àwọn ààrá tó rinlẹ̀. Wọ́n sọ pé: “Ẹ yin Jáà,*+ torí Jèhófà* Ọlọ́run wa, Olódùmarè,+ ti bẹ̀rẹ̀ sí í jọba!+
10 Ẹ kéde láàárín àwọn orílẹ̀-èdè pé: “Jèhófà ti di Ọba!+ Ayé* fìdí múlẹ̀ gbọn-in gbọn-in, kò ṣeé ṣí nípò.* Òun yóò dá ẹjọ́ àwọn èèyàn* lọ́nà tí ó tọ́.”+
7 Wo bí ẹsẹ̀ ẹni tó ń mú ìhìn rere wá ṣe rẹwà tó lórí àwọn òkè,+Ẹni tó ń kéde àlàáfíà,+Ẹni tó ń mú ìhìn rere wá nípa ohun tó sàn,Ẹni tó ń kéde ìgbàlà,Ẹni tó ń sọ fún Síónì pé: “Ọlọ́run rẹ ti di Ọba!”+
17 wọ́n ní: “A dúpẹ́ lọ́wọ́ rẹ, Jèhófà* Ọlọ́run, Olódùmarè, ẹni tó ti wà tipẹ́, tó sì wà báyìí,+ torí o ti gba agbára ńlá rẹ, o sì ti ń jọba.+
6 Mo sì gbọ́ ohun tó dún bí ohùn àwọn tó pọ̀ gan-an àti bí ìró omi tó pọ̀ àti bí ìró àwọn ààrá tó rinlẹ̀. Wọ́n sọ pé: “Ẹ yin Jáà,*+ torí Jèhófà* Ọlọ́run wa, Olódùmarè,+ ti bẹ̀rẹ̀ sí í jọba!+