ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Nehemáyà 3
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Nehemáyà

      • Wọ́n tún ògiri náà kọ́ (1-32)

Nehemáyà 3:1

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 12:10; 13:4, 28
  • +Jo 5:2
  • +Ne 12:30
  • +Ne 12:38, 39
  • +Jer 31:38; Sek 14:10

Nehemáyà 3:2

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹsr 2:1, 34

Nehemáyà 3:3

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Kr 33:1, 14; Sef 1:10
  • +Ne 2:7, 8

Nehemáyà 3:4

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹsr 8:33; Ne 3:21
  • +Ne 3:30; 6:17, 18

Nehemáyà 3:5

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “kò tẹ ẹ̀yìn ọrùn wọn ba láti ṣe.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 3:27; Emọ 1:1

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    2/1/2006, ojú ìwé 10

Nehemáyà 3:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 12:38, 39

Nehemáyà 3:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “tí wọ́n jẹ́ ti ìtẹ́.”

  • *

    Tàbí “Òdìkejì odò Yúfírétì.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 21:2
  • +Joṣ 18:21, 26; 2Kr 16:6; Jer 40:6
  • +Jẹ 15:18

Nehemáyà 3:8

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “àwọn tó ń ṣe lọ́fíńdà.”

  • *

    Tàbí “òkúta palaba-palaba.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 12:38

Nehemáyà 3:11

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “apá kan tí wọ́n wọ̀n.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹsr 2:1, 32
  • +Ẹsr 2:1, 6
  • +Ne 12:38

Nehemáyà 3:12

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́ (Ẹ̀dà Tó Wà fún Ìkẹ́kọ̀ọ́),

    10/2019, ojú ìwé 23

Nehemáyà 3:13

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Nǹkan bíi mítà 445 (1,460 ẹsẹ̀ bàtà). Wo Àfikún B14.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 15:20, 34; Ne 11:25, 30
  • +2Kr 26:9
  • +Ne 2:13

Nehemáyà 3:14

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 6:1

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Jeremáyà, ojú ìwé 159-160

Nehemáyà 3:15

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ṣélà túmọ̀ sí “Ipa Odò.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 18:21, 26
  • +Ne 2:14; 12:37
  • +Ais 22:9
  • +Jer 39:4
  • +Ne 12:37
  • +2Sa 5:7

Nehemáyà 3:16

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 15:20, 58; 2Kr 11:5-7
  • +1Ọb 2:10; 2Kr 16:13, 14
  • +Ne 2:14

Nehemáyà 3:17

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 15:20, 44

Nehemáyà 3:19

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹsr 2:1, 40
  • +2Kr 26:9; Ne 3:24

Nehemáyà 3:20

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹsr 10:28, 44
  • +Ne 3:1; 13:4

Nehemáyà 3:21

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹsr 8:33

Nehemáyà 3:22

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí kó jẹ́, “agbègbè tó wà nítòsí.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jẹ 13:10

Nehemáyà 3:24

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 3:19

Nehemáyà 3:25

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Ààfin.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Sa 5:11; Ne 12:37
  • +Jer 37:21
  • +Ẹsr 2:1, 3

Nehemáyà 3:26

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Nétínímù.” Ní Héb., “àwọn tí a fi fúnni.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Joṣ 9:3, 27; 1Kr 9:2; Ẹsr 2:43-54; 8:17, 20
  • +2Kr 27:1, 3; 33:1, 14; Ne 11:21
  • +Ne 8:1; 12:37

Nehemáyà 3:27

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 3:5

Nehemáyà 3:28

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Jer 31:40

Nehemáyà 3:29

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 13:13
  • +1Kr 9:17, 18

Nehemáyà 3:30

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 6:17, 18

Nehemáyà 3:31

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Nétínímù.” Ní Héb., “àwọn tí a fi fúnni.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 3:26

Nehemáyà 3:32

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 3:1; Jo 5:2

Àwọn míì

Neh. 3:1Ne 12:10; 13:4, 28
Neh. 3:1Jo 5:2
Neh. 3:1Ne 12:30
Neh. 3:1Ne 12:38, 39
Neh. 3:1Jer 31:38; Sek 14:10
Neh. 3:2Ẹsr 2:1, 34
Neh. 3:32Kr 33:1, 14; Sef 1:10
Neh. 3:3Ne 2:7, 8
Neh. 3:4Ẹsr 8:33; Ne 3:21
Neh. 3:4Ne 3:30; 6:17, 18
Neh. 3:5Ne 3:27; Emọ 1:1
Neh. 3:6Ne 12:38, 39
Neh. 3:72Sa 21:2
Neh. 3:7Joṣ 18:21, 26; 2Kr 16:6; Jer 40:6
Neh. 3:7Jẹ 15:18
Neh. 3:8Ne 12:38
Neh. 3:11Ẹsr 2:1, 32
Neh. 3:11Ẹsr 2:1, 6
Neh. 3:11Ne 12:38
Neh. 3:13Joṣ 15:20, 34; Ne 11:25, 30
Neh. 3:132Kr 26:9
Neh. 3:13Ne 2:13
Neh. 3:14Jer 6:1
Neh. 3:15Joṣ 18:21, 26
Neh. 3:15Ne 2:14; 12:37
Neh. 3:15Ais 22:9
Neh. 3:15Jer 39:4
Neh. 3:15Ne 12:37
Neh. 3:152Sa 5:7
Neh. 3:16Joṣ 15:20, 58; 2Kr 11:5-7
Neh. 3:161Ọb 2:10; 2Kr 16:13, 14
Neh. 3:16Ne 2:14
Neh. 3:17Joṣ 15:20, 44
Neh. 3:19Ẹsr 2:1, 40
Neh. 3:192Kr 26:9; Ne 3:24
Neh. 3:20Ẹsr 10:28, 44
Neh. 3:20Ne 3:1; 13:4
Neh. 3:21Ẹsr 8:33
Neh. 3:22Jẹ 13:10
Neh. 3:24Ne 3:19
Neh. 3:252Sa 5:11; Ne 12:37
Neh. 3:25Jer 37:21
Neh. 3:25Ẹsr 2:1, 3
Neh. 3:26Joṣ 9:3, 27; 1Kr 9:2; Ẹsr 2:43-54; 8:17, 20
Neh. 3:262Kr 27:1, 3; 33:1, 14; Ne 11:21
Neh. 3:26Ne 8:1; 12:37
Neh. 3:27Ne 3:5
Neh. 3:28Jer 31:40
Neh. 3:291Kr 9:17, 18
Neh. 3:29Ne 13:13
Neh. 3:30Ne 6:17, 18
Neh. 3:31Ne 3:26
Neh. 3:32Ne 3:1; Jo 5:2
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
  • 29
  • 30
  • 31
  • 32
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Nehemáyà 3:1-32

Nehemáyà

3 Élíáṣíbù+ àlùfáà àgbà àti àwọn arákùnrin rẹ̀, àwọn àlùfáà, dìde láti kọ́ Ẹnubodè Àgùntàn.+ Wọ́n yà á sí mímọ́,+ wọ́n sì gbé àwọn ilẹ̀kùn rẹ̀ nàró; wọ́n yà á sí mímọ́ títí dé Ilé Gogoro Méà+ àti títí dé Ilé Gogoro Hánánélì.+ 2 Apá tó tẹ̀ lé tiwọn ni àwọn ọkùnrin Jẹ́ríkò+ mọ; Sákúrì ọmọ Ímúrì sì mọ apá tó tẹ̀ lé tiwọn.

3 Àwọn ọmọ Hásénà mọ Ẹnubodè Ẹja;+ wọ́n fi ẹ̀là gẹdú kọ́ ọ,+ lẹ́yìn náà, wọ́n gbé àwọn ilẹ̀kùn rẹ̀ sí i àti àwọn ìkọ́ rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ọ̀pá ìdábùú rẹ̀. 4 Apá tó tẹ̀ lé tiwọn ni Mérémótì + ọmọ Úríjà ọmọ Hákósì ti ṣe iṣẹ́ àtúnṣe, Méṣúlámù+ ọmọ Berekáyà ọmọ Meṣesábélì sì ṣe iṣẹ́ àtúnṣe ní apá tó tẹ̀ lé tiwọn, bákan náà Sádókù ọmọ Béánà ṣe iṣẹ́ àtúnṣe ní apá tó tẹ̀ lé tiwọn. 5 Apá tó tẹ̀ lé tiwọn ni àwọn ará Tékóà+ ti ṣe iṣẹ́ àtúnṣe, àmọ́ àwọn olókìkí àárín wọn kò rẹ ara wọn sílẹ̀ láti ṣe nínú* iṣẹ́ àwọn ọ̀gá wọn.

6 Jóyádà ọmọ Páséà àti Méṣúlámù ọmọ Besodeáyà tún Ẹnubodè Ìlú Àtijọ́+ ṣe; wọ́n fi ẹ̀là gẹdú kọ́ ọ, wọ́n sì gbé àwọn ilẹ̀kùn rẹ̀ sí i àti àwọn ìkọ́ rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ọ̀pá ìdábùú rẹ̀. 7 Apá tó tẹ̀ lé tiwọn ni Melatáyà ará Gíbíónì+ àti Jádónì ará Mérónótì ti ṣe iṣẹ́ àtúnṣe, àwọn ọkùnrin Gíbíónì àti ti Mísípà,+ tí wọ́n wà lábẹ́ àṣẹ* gómìnà agbègbè tó wà ní Ìkọjá Odò.*+ 8 Apá tó tẹ̀ lé tiwọn ni Úsíélì ọmọ Háháyà, ọ̀kan lára àwọn alágbẹ̀dẹ wúrà ti ṣe iṣẹ́ àtúnṣe, Hananáyà, ọ̀kan lára àwọn olùpo òróró ìpara,* ṣe iṣẹ́ àtúnṣe ní apá tó tẹ̀ lé tirẹ̀; wọ́n sì fi òkúta* tẹ́ ilẹ̀ Jerúsálẹ́mù títí dé Ògiri Fífẹ̀.+ 9 Apá tó tẹ̀ lé tiwọn ni Refáyà ọmọ Húrì, olórí ìdajì agbègbè Jerúsálẹ́mù ti ṣe iṣẹ́ àtúnṣe. 10 Apá tó tẹ̀ lé tiwọn ni Jedáyà ọmọ Hárúmáfù ti ṣe iṣẹ́ àtúnṣe ní iwájú ilé òun fúnra rẹ̀; Hátúṣì ọmọ Haṣabanéáyà sì ṣe iṣẹ́ àtúnṣe ní apá tó tẹ̀ lé tirẹ̀.

11 Málíkíjà ọmọ Hárímù+ àti Háṣúbù ọmọ Pahati-móábù+ tún ẹ̀ka míì* ṣe àti Ilé Gogoro Ààrò.+ 12 Apá tó tẹ̀ lé tiwọn ni Ṣálúmù ọmọ Hálóhéṣì, olórí ìdajì agbègbè Jerúsálẹ́mù ti ṣe iṣẹ́ àtúnṣe pẹ̀lú àwọn ọmọbìnrin rẹ̀.

13 Hánúnì àti àwọn tó ń gbé ní Sánóà+ tún Ẹnubodè Àfonífojì ṣe;+ wọ́n kọ́ ọ, wọ́n gbé ilẹ̀kùn rẹ̀ sí i àti àwọn ìkọ́ rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ọ̀pá ìdábùú rẹ̀, wọ́n ṣàtúnṣe ẹgbẹ̀rún (1,000) ìgbọ̀nwọ́* lára ògiri náà títí dé Ẹnubodè Òkìtì Eérú.+ 14 Málíkíjà ọmọ Rékábù, olórí ní agbègbè Bẹti-hákérémù+ tún Ẹnubodè Òkìtì Eérú ṣe; ó kọ́ ọ, ó sì gbé àwọn ilẹ̀kùn rẹ̀ sí i àti àwọn ìkọ́ rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ọ̀pá ìdábùú rẹ̀.

15 Ṣálúnì ọmọ Kólíhósè, olórí ní agbègbè Mísípà+ tún Ẹnubodè Ojúsun + ṣe; ó kọ́ ọ, ó ṣe òrùlé rẹ̀, ó sì gbé àwọn ilẹ̀kùn rẹ̀ sí i àti àwọn ìkọ́ rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ọ̀pá ìdábùú rẹ̀, ó tún ṣàtúnṣe ògiri Adágún+ Ṣélà* tó lọ sí Ọgbà Ọba+ títí dé Àtẹ̀gùn+ tó sọ̀ kalẹ̀ látinú Ìlú Dáfídì.+

16 Lẹ́yìn rẹ̀, Nehemáyà ọmọ Ásíbúkì, olórí ìdajì agbègbè Bẹti-súrì+ ṣe iṣẹ́ àtúnṣe láti iwájú Àwọn Ibi Ìsìnkú Ilé Dáfídì+ títí dé odò+ àtọwọ́dá àti títí dé Ilé Àwọn Alágbára.

17 Lẹ́yìn rẹ̀, àwọn ọmọ Léfì tó ṣe iṣẹ́ àtúnṣe nìyí: Réhúmù ọmọ Bánì; ẹni tó tẹ̀ lé e ni Haṣabáyà, olórí ìdajì agbègbè Kéílà,+ ó ṣe iṣẹ́ àtúnṣe fún agbègbè rẹ̀. 18 Lẹ́yìn rẹ̀, àwọn arákùnrin wọn tó ṣe iṣẹ́ àtúnṣe nìyí: Báfáì ọmọ Hénádádì, olórí ìdajì agbègbè Kéílà.

19 Ésérì ọmọ Jéṣúà+ tó jẹ́ olórí ní Mísípà ṣe àtúnṣe ẹ̀ka míì ní apá tó tẹ̀ lé e níwájú ìgòkè tó lọ sí Ilé Ìhámọ́ra Níbi Ìtì Ògiri.+

20 Lẹ́yìn rẹ̀, Bárúkù ọmọ Sábáì+ fi ìtara ṣiṣẹ́, ó sì tún ẹ̀ka míì ṣe, láti Ìtì Ògiri títí dé ẹnu ọ̀nà ilé Élíáṣíbù+ àlùfáà àgbà.

21 Lẹ́yìn rẹ̀, Mérémótì+ ọmọ Úríjà ọmọ Hákósì tún ẹ̀ka míì ṣe, láti ẹnu ọ̀nà ilé Élíáṣíbù títí dé òpin ilé Élíáṣíbù.

22 Lẹ́yìn rẹ̀, àwọn àlùfáà agbègbè Jọ́dánì,*+ ṣe iṣẹ́ àtúnṣe. 23 Lẹ́yìn wọn, Bẹ́ńjámínì àti Háṣúbù ṣe iṣẹ́ àtúnṣe níwájú ilé àwọn fúnra wọn. Lẹ́yìn wọn, Asaráyà ọmọ Maaseáyà ọmọ Ananíà ṣe iṣẹ́ àtúnṣe nítòsí ilé rẹ̀. 24 Lẹ́yìn rẹ̀, Bínúì ọmọ Hénádádì tún ẹ̀ka míì ṣe, láti ilé Asaráyà títí dé Ìtì Ògiri + àti títí dé igun odi.

25 Lẹ́yìn rẹ̀, Pálálì ọmọ Úṣáì ṣe iṣẹ́ àtúnṣe níwájú Ìtì Ògiri àti ilé gogoro tó yọ jáde láti Ilé Ọba,*+ ti apá òkè tó jẹ́ ti Àgbàlá Ẹ̀ṣọ́.+ Lẹ́yìn rẹ̀, ó kan Pedáyà ọmọ Páróṣì.+

26 Àwọn ìránṣẹ́ tẹ́ńpìlì*+ tí wọ́n ń gbé ní Ófélì+ ṣe iṣẹ́ àtúnṣe títí dé iwájú Ẹnubodè Omi+ ní ìlà oòrùn àti ilé gogoro tó yọ jáde náà.

27 Lẹ́yìn wọn, àwọn ará Tékóà+ tún ẹ̀ka míì ṣe, láti iwájú ilé gogoro ńlá tó yọ jáde, títí dé ògiri Ófélì.

28 Àwọn àlùfáà ṣe iṣẹ́ àtúnṣe lórí Ẹnubodè Ẹṣin,+ kálukú ṣiṣẹ́ níwájú ilé rẹ̀.

29 Lẹ́yìn wọn, Sádókù+ ọmọ Ímérì ṣe iṣẹ́ àtúnṣe níwájú ilé rẹ̀.

Ẹ̀yìn rẹ̀ ni Ṣemáyà ọmọ Ṣẹkanáyà, olùṣọ́ Ẹnubodè Ìlà Oòrùn,+ ṣe iṣẹ́ àtúnṣe.

30 Lẹ́yìn rẹ̀, Hananáyà ọmọ Ṣelemáyà àti Hánúnì ọmọ kẹfà tí Sáláfù bí tún ẹ̀ka míì ṣe.

Lẹ́yìn rẹ̀, Méṣúlámù+ ọmọ Berekáyà ṣe iṣẹ́ àtúnṣe níwájú gbọ̀ngàn òun fúnra rẹ̀.

31 Lẹ́yìn rẹ̀, Málíkíjà tó jẹ́ ọmọ ẹgbẹ́ alágbẹ̀dẹ wúrà, ṣe iṣẹ́ àtúnṣe títí dé ilé àwọn ìránṣẹ́ tẹ́ńpìlì*+ àti àwọn oníṣòwò, níwájú Ẹnubodè Àbẹ̀wò àti títí dé yàrá tó wà lórí igun odi.

32 Àárín yàrá tó wà lórí igun odi àti Ẹnubodè Àgùntàn+ sì ni àwọn alágbẹ̀dẹ wúrà àti àwọn oníṣòwò ti ṣe iṣẹ́ àtúnṣe.

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́