ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Sáàmù 116
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Sáàmù

      • Orin ọpẹ́

        • “Kí ni màá san pa dà fún Jèhófà?” (12)

        • “Màá gbé ife ìgbàlà” (13)

        • “Màá san àwọn ẹ̀jẹ́ mi fún Jèhófà” (14, 18)

        • Àdánù ńlá ni ikú àwọn adúróṣinṣin (15)

Sáàmù 116:1

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí kó jẹ́, “Mo nífẹ̀ẹ́ nítorí Jèhófà ń gbọ́.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 18:6

Sáàmù 116:2

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ó ń bẹ̀rẹ̀ kí ó lè fetí.”

  • *

    Ní Héb., “ní ọjọ́ ayé mi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 34:15

Sáàmù 116:3

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “Àwọn ìdààmú Ṣìọ́ọ̀lù wá mi rí.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ais 38:10
  • +Sm 18:4; 38:6

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Àwọn Ìtẹ̀jáde Tá A Tọ́ka sí Nínú Ìwé Ìpàdé,

    8/2016,

Sáàmù 116:4

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “gba ọkàn mi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 34:6; Ro 10:13

Sáàmù 116:5

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “olóore ọ̀fẹ́.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 32:4
  • +Ẹk 34:6; Ne 9:17; Da 9:9

Sáàmù 116:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 19:7

Sáàmù 116:7

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Wo Àlàyé Ọ̀rọ̀.

Sáàmù 116:8

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “gba ọkàn mi.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 56:13; 94:18

Sáàmù 116:10

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +2Kọ 4:13

Sáàmù 116:11

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ro 3:4

Sáàmù 116:12

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    7/15/2009, ojú ìwé 29-30

    12/1/1998, ojú ìwé 24

Sáàmù 116:13

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “ìgbàlà ńlá.”

Sáàmù 116:14

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 22:25; Jon 2:9

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    7/15/2009, ojú ìwé 29-30

Sáàmù 116:15

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ní Héb., “iyebíye.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +1Sa 25:29; Job 1:12; Sm 91:14; Sek 2:8; 2Pe 2:9

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    8/15/2012, ojú ìwé 30

    5/15/2012, ojú ìwé 22

    9/1/2006, ojú ìwé 14

Sáàmù 116:16

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 107:14

Sáàmù 116:17

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 7:12; Sm 50:23

Sáàmù 116:18

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 22:25; 76:11
  • +Sm 116:14

Sáàmù 116:19

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Halelúyà!” “Jáà” ni ìkékúrú Jèhófà.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Sm 96:8
  • +Ifi 19:1

Àwọn míì

Sm 116:1Sm 18:6
Sm 116:2Sm 34:15
Sm 116:3Ais 38:10
Sm 116:3Sm 18:4; 38:6
Sm 116:4Sm 34:6; Ro 10:13
Sm 116:5Di 32:4
Sm 116:5Ẹk 34:6; Ne 9:17; Da 9:9
Sm 116:6Sm 19:7
Sm 116:8Sm 56:13; 94:18
Sm 116:102Kọ 4:13
Sm 116:11Ro 3:4
Sm 116:14Sm 22:25; Jon 2:9
Sm 116:151Sa 25:29; Job 1:12; Sm 91:14; Sek 2:8; 2Pe 2:9
Sm 116:16Sm 107:14
Sm 116:17Le 7:12; Sm 50:23
Sm 116:18Sm 22:25; 76:11
Sm 116:18Sm 116:14
Sm 116:19Sm 96:8
Sm 116:19Ifi 19:1
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Sáàmù 116:1-19

Sáàmù

116 Mo nífẹ̀ẹ́ Jèhófà

Nítorí ó ń gbọ́* ohùn mi, ẹ̀bẹ̀ mi fún ìrànlọ́wọ́.+

 2 Nítorí ó ń tẹ́tí* sí mi,+

Èmi yóò máa ké pè é ní gbogbo ìgbà tí mo bá wà láàyè.*

 3 Àwọn okùn ikú yí mi ká;

Isà Òkú dì mí mú.*+

Ìdààmú àti ẹ̀dùn ọkàn bò mí mọ́lẹ̀.+

 4 Àmọ́ mo ké pe orúkọ Jèhófà,+ mo ní:

“Jèhófà, gbà mí* sílẹ̀!”

 5 Jèhófà jẹ́ agbatẹnirò* àti olódodo;+

Ọlọ́run wa jẹ́ aláàánú.+

 6 Jèhófà ń ṣọ́ àwọn aláìmọ̀kan.+

Wọ́n rẹ̀ mí sílẹ̀, àmọ́ ó gbà mí.

 7 Kí ọkàn* mi rí ìsinmi lẹ́ẹ̀kan sí i,

Nítorí Jèhófà ti fi inú rere hàn sí mi.

 8 O ti gbà mí* lọ́wọ́ ikú,

O gba ojú mi lọ́wọ́ omijé, o sì gba ẹsẹ̀ mi lọ́wọ́ ìkọ̀sẹ̀.+

 9 Ṣe ni èmi yóò máa rìn níwájú Jèhófà ní ilẹ̀ alààyè.

10 Mo nígbàgbọ́, torí náà mo sọ̀rọ̀;+

Ìyà jẹ mí gan-an.

11 Ní tèmi, jìnnìjìnnì bò mí, mo sọ pé:

“Òpùrọ́ ni gbogbo èèyàn.”+

12 Kí ni màá san pa dà fún Jèhófà

Lórí gbogbo oore tó ṣe fún mi?

13 Màá gbé ife ìgbàlà,*

Màá sì ké pe orúkọ Jèhófà.

14 Màá san àwọn ẹ̀jẹ́ mi fún Jèhófà

Níwájú gbogbo àwọn èèyàn rẹ̀.+

15 Lójú Jèhófà, àdánù ńlá*

Ni ikú àwọn ẹni ìdúróṣinṣin rẹ̀.+

16 Mo bẹ̀ ọ́, Jèhófà,

Nítorí ìránṣẹ́ rẹ ni mí.

Ìránṣẹ́ rẹ ni mí, ọmọ ẹrúbìnrin rẹ.

O ti tú ìdè mi.+

17 Màá rú ẹbọ ọpẹ́ sí ọ;+

Màá ké pe orúkọ Jèhófà.

18 Màá san àwọn ẹ̀jẹ́ mi fún Jèhófà+

Níwájú gbogbo àwọn èèyàn rẹ̀,+

19 Nínú àwọn àgbàlá ilé Jèhófà,+

Láàárín rẹ, ìwọ Jerúsálẹ́mù.

Ẹ yin Jáà!*+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́