ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍNTÁNẸ́Ẹ̀TÌ ti Watchtower
ÀKÁ ÌWÉ ORÍ ÍŃTÁNẸ́Ẹ̀TÌ
ti Watchtower
Yorùbá
ọ́
  • ẹ
  • ọ
  • ṣ
  • ń
  • ẹ́
  • ẹ̀
  • ọ́
  • ọ̀
  • BÍBÉLÌ
  • ÌTẸ̀JÁDE
  • ÌPÀDÉ
  • Nehemáyà 10
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun

Kò sí fídíò kankan ní apá yìí.

Má bínú, fídíò yìí kò jáde.

Ohun Tó Wà Nínú Ìwé Nehemáyà

      • Àwọn èèyàn náà gbà láti máa pa Òfin mọ́ (1-39)

        • ‘A kò ní pa ilé Ọlọ́run wa tì’ (39)

Nehemáyà 10:1

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Tíṣátà,” orúkọ oyè tí àwọn ará Páṣíà fún gómìnà ìpínlẹ̀.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 9:38

Nehemáyà 10:5

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹsr 2:1, 39

Nehemáyà 10:6

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹsr 8:1, 2

Nehemáyà 10:9

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹsr 3:9; Ne 12:8

Nehemáyà 10:12

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 12:24

Nehemáyà 10:14

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 7:6, 11

Nehemáyà 10:28

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “Nétínímù.” Ní Héb., “àwọn tí a fi fúnni.”

  • *

    Tàbí kó jẹ́, “àwọn tó dàgbà tó láti lóye.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ne 8:1; 9:2

Nehemáyà 10:30

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 34:15, 16; Di 7:3, 4

Nehemáyà 10:31

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 20:10
  • +Ẹk 12:16; Nọ 29:1, 12
  • +Ẹk 23:10, 11; Le 25:4, 5
  • +Di 15:1-3

Nehemáyà 10:32

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ṣékélì kan jẹ́ gíráàmù 11.4. Wo Àfikún B14.

  • *

    Tàbí “tẹ́ńpìlì.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 30:13

Nehemáyà 10:33

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Ìyẹn, búrẹ́dì àfihàn.

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 24:5-7
  • +Ẹk 29:40, 41
  • +Nọ 28:9
  • +Nọ 28:11-13; 1Kr 23:31
  • +Di 16:16
  • +Le 16:15

Nehemáyà 10:34

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Le 1:7; 6:12, 13

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    2/1/2006, ojú ìwé 11

Nehemáyà 10:35

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 23:19; Nọ 18:8, 13; Di 26:2

Nehemáyà 10:36

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Ẹk 13:2; Nọ 18:15
  • +Nọ 18:8, 11; 1Kọ 9:13

Nehemáyà 10:37

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “àwọn gbọ̀ngàn ìjẹun.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 15:20
  • +Le 27:30
  • +Nọ 18:8, 12; Di 18:1, 4
  • +2Kr 31:11
  • +Nọ 18:21

Nehemáyà 10:38

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “àwọn gbọ̀ngàn ìjẹun.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Nọ 18:26

Nehemáyà 10:39

Àlàyé ìsàlẹ́ ìwé

  • *

    Tàbí “àwọn gbọ̀ngàn ìjẹun.”

Atọ́ka Àárín Ìwé

  • +Di 12:5, 6
  • +Di 14:23
  • +Ne 13:10, 11

Atọ́ka

  • Ìwé Ìwádìí

    Ilé Ìṣọ́,

    10/15/1998, ojú ìwé 21-22

Àwọn míì

Neh. 10:1Ne 9:38
Neh. 10:5Ẹsr 2:1, 39
Neh. 10:6Ẹsr 8:1, 2
Neh. 10:9Ẹsr 3:9; Ne 12:8
Neh. 10:12Ne 12:24
Neh. 10:14Ne 7:6, 11
Neh. 10:28Ne 8:1; 9:2
Neh. 10:30Ẹk 34:15, 16; Di 7:3, 4
Neh. 10:31Ẹk 20:10
Neh. 10:31Ẹk 12:16; Nọ 29:1, 12
Neh. 10:31Ẹk 23:10, 11; Le 25:4, 5
Neh. 10:31Di 15:1-3
Neh. 10:32Ẹk 30:13
Neh. 10:33Le 24:5-7
Neh. 10:33Ẹk 29:40, 41
Neh. 10:33Nọ 28:9
Neh. 10:33Nọ 28:11-13; 1Kr 23:31
Neh. 10:33Di 16:16
Neh. 10:33Le 16:15
Neh. 10:34Le 1:7; 6:12, 13
Neh. 10:35Ẹk 23:19; Nọ 18:8, 13; Di 26:2
Neh. 10:36Ẹk 13:2; Nọ 18:15
Neh. 10:36Nọ 18:8, 11; 1Kọ 9:13
Neh. 10:37Nọ 15:20
Neh. 10:37Le 27:30
Neh. 10:37Nọ 18:8, 12; Di 18:1, 4
Neh. 10:372Kr 31:11
Neh. 10:37Nọ 18:21
Neh. 10:38Nọ 18:26
Neh. 10:39Di 12:5, 6
Neh. 10:39Di 14:23
Neh. 10:39Ne 13:10, 11
  • Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
  • 1
  • 2
  • 3
  • 4
  • 5
  • 6
  • 7
  • 8
  • 9
  • 10
  • 11
  • 12
  • 13
  • 14
  • 15
  • 16
  • 17
  • 18
  • 19
  • 20
  • 21
  • 22
  • 23
  • 24
  • 25
  • 26
  • 27
  • 28
  • 29
  • 30
  • 31
  • 32
  • 33
  • 34
  • 35
  • 36
  • 37
  • 38
  • 39
Bíbélì Mímọ́ ti Ìtumọ̀ Ayé Tuntun
Nehemáyà 10:1-39

Nehemáyà

10 Àwọn tó fọwọ́ sí i, tí wọ́n sì gbé èdìdì wọn lé e+ ni:

Nehemáyà, tó jẹ́ gómìnà,* ọmọ Hakaláyà

Àti Sedekáyà, 2 Seráyà, Asaráyà, Jeremáyà, 3 Páṣúrì, Amaráyà, Málíkíjà, 4 Hátúṣì, Ṣebanáyà, Málúkù, 5 Hárímù,+ Mérémótì, Ọbadáyà, 6 Dáníẹ́lì,+ Gínétónì, Bárúkù, 7 Méṣúlámù, Ábíjà, Míjámínì, 8 Maasáyà, Bílígáì àti Ṣemáyà; àwọn yìí jẹ́ àlùfáà.

9 Àwọn ọmọ Léfì tó fọwọ́ sí i ni: Jéṣúà ọmọ Asanáyà, Bínúì látinú àwọn ọmọ Hénádádì, Kádímíélì+ 10 àti arákùnrin wọn Ṣebanáyà, Hodáyà, Kélítà, Pẹláyà, Hánánì, 11 Máíkà, Réhóbù, Haṣabáyà, 12 Sákúrì, Ṣerebáyà,+ Ṣebanáyà, 13 Hodáyà, Bánì àti Bẹnínù.

14 Àwọn olórí àwọn èèyàn náà tó fọwọ́ sí i ni: Páróṣì, Pahati-móábù,+ Élámù, Sátù, Bánì, 15 Búnì, Ásígádì, Bébáì, 16 Ádóníjà, Bígífáì, Ádínì, 17 Átérì, Hẹsikáyà, Ásúrì, 18 Hodáyà, Háṣúmù, Bísáì, 19 Hárífù, Ánátótì, Nébáì, 20 Mágípíáṣì, Méṣúlámù, Hésírì, 21 Meṣesábélì, Sádókù, Jádúà, 22 Pẹlatáyà, Hánánì, Ánáyà, 23 Hóṣéà, Hananáyà, Háṣúbù, 24 Hálóhéṣì, Pílíhà, Ṣóbékì, 25 Réhúmù, Háṣábínà, Maaseáyà, 26 Áhíjà, Hánánì, Ánánì, 27 Málúkù, Hárímù àti Báánà.

28 Ìyókù àwọn èèyàn náà, ìyẹn àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Léfì, àwọn aṣọ́bodè, àwọn akọrin, àwọn ìránṣẹ́ tẹ́ńpìlì* àti gbogbo àwọn tó ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn èèyàn ilẹ̀ tó yí wọn ká kí wọ́n lè pa Òfin Ọlọ́run tòótọ́ mọ́,+ pẹ̀lú àwọn ìyàwó wọn, àwọn ọmọkùnrin wọn àti àwọn ọmọbìnrin wọn, gbogbo àwọn tó ní ìmọ̀ àti òye,* 29 dara pọ̀ mọ́ àwọn arákùnrin wọn, àwọn olókìkí àárín wọn, wọ́n gégùn-ún, wọ́n sì búra pé wọ́n á máa rìn nínú Òfin Ọlọ́run tòótọ́, èyí tó wá nípasẹ̀ Mósè ìránṣẹ́ Ọlọ́run tòótọ́ àti pé àwọn á rí i pé àwọn ń pa gbogbo àṣẹ Jèhófà Olúwa wa mọ́ àti àwọn ìdájọ́ rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ìlànà rẹ̀. 30 A kò ní fi àwọn ọmọbìnrin wa fún àwọn èèyàn ilẹ̀ náà, a kò sì ní fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin wa.+

31 Tí àwọn èèyàn ilẹ̀ náà bá kó ọjà tàbí oríṣiríṣi ọkà wá ní ọjọ́ Sábáàtì, a kò ní ra ohunkóhun lọ́wọ́ wọn ní Sábáàtì+ tàbí ní ọjọ́ mímọ́.+ A tún máa fi irè oko wa tó bá jáde ní ọdún keje+ sílẹ̀ àti gbogbo gbèsè tí ẹnikẹ́ni bá jẹ wá.+

32 Bákan náà, a gbé àṣẹ kan kalẹ̀ fún ara wa lẹ́nì kọ̀ọ̀kan pé, a ó máa mú ìdá mẹ́ta ṣékélì* wá lọ́dọọdún fún iṣẹ́ ìsìn ilé* Ọlọ́run wa,+ 33 fún búrẹ́dì onípele,*+ ọrẹ ọkà ìgbà gbogbo,+ ẹbọ sísun ìgbà gbogbo ti Sábáàtì+ pẹ̀lú ti òṣùpá tuntun+ àti fún àwọn àsè tí a yàn,+ àwọn ohun mímọ́ àti ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀+ láti ṣe ètùtù fún Ísírẹ́lì àti fún gbogbo iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa.

34 A tún ṣẹ́ kèké lórí bí àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Léfì àti àwọn èèyàn náà á ṣe máa mú igi wá sí ilé Ọlọ́run wa, ní agboolé-agboolé àwọn bàbá wa, ní àkókò tí a yàn lọ́dọọdún, láti máa fi dáná lórí pẹpẹ Jèhófà Ọlọ́run wa, bó ṣe wà lákọsílẹ̀ nínú Òfin.+ 35 A ó tún máa mú àkọ́so èso ilẹ̀ wa àti àkọ́so èso oríṣiríṣi igi wá lọ́dọọdún sí ilé Jèhófà+ 36 àti àkọ́bí àwọn ọmọkùnrin wa àti ti ẹran ọ̀sìn wa+ pẹ̀lú àkọ́bí ọ̀wọ́ ẹran wa àti ti agbo ẹran wa bó ṣe wà lákọsílẹ̀ nínú Òfin. A ó mú wọn wá sí ilé Ọlọ́run wa, sọ́dọ̀ àwọn àlùfáà tó ń ṣiṣẹ́ nínú ilé Ọlọ́run wa.+ 37 Bákan náà, a ó máa mú àkọ́so ọkà tí a kò lọ̀ kúnná+ wá àti àwọn ọrẹ pẹ̀lú èso oríṣiríṣi igi+ àti wáìnì tuntun pẹ̀lú òróró,+ a ó sì kó wọn wá fún àwọn àlùfáà ní àwọn yàrá tí wọ́n ń kó nǹkan pa mọ́ sí* ní ilé Ọlọ́run wa,+ a ó sì kó ìdá mẹ́wàá irè oko ilẹ̀ wa fún àwọn ọmọ Léfì,+ torí àwọn ni wọ́n ń gba ìdá mẹ́wàá ní gbogbo ìlú tí a ti ń ṣiṣẹ́ àgbẹ̀.

38 Kí àlùfáà, ọmọ Áárónì, wà pẹ̀lú àwọn ọmọ Léfì nígbà tí àwọn ọmọ Léfì bá ń gba ìdá mẹ́wàá; kí àwọn ọmọ Léfì mú ìdá mẹ́wàá lára ìdá mẹ́wàá ti ilé Ọlọ́run wa,+ kí wọ́n sì kó o sí àwọn yàrá* tó wà ní ilé ìkẹ́rùsí. 39 Inú àwọn yàrá tí wọ́n ń kó nǹkan pa mọ́ sí* ni kí àwọn ọmọ Ísírẹ́lì àti àwọn ọmọ Léfì máa mú ọrẹ+ ọkà, wáìnì tuntun àti òróró wá,+ ibẹ̀ sì ni kí àwọn nǹkan èlò ibi mímọ́ máa wà títí kan àwọn àlùfáà tó ń ṣiṣẹ́ ìsìn àti àwọn aṣọ́bodè pẹ̀lú àwọn akọrin. A kò sì ní pa ilé Ọlọ́run wa tì.+

Yorùbá Publications (1987-2025)
Jáde
Wọlé
  • Yorùbá
  • Fi Ráńṣẹ́
  • Èyí tí mo fẹ́ràn jù
  • Copyright © 2025 Watch Tower Bible and Tract Society of Pennsylvania
  • Àdéhùn Nípa Lílò
  • Òfin
  • Ètò Nípa Ìsọfúnni Rẹ
  • JW.ORG
  • Wọlé
Fi Ráńṣẹ́